Àlàyé Ìsàlẹ̀ Ìwé
a Nínú èdè tí wọ́n fi kọ Bíbélì, àwọn ọ̀rọ̀ tá a tú sí “ọkàn” tún lè túmọ̀ ní tààràtà sí “èémí.” Ó tún túmọ̀ sí ohun tí kò ṣeé fojú rí ṣùgbọ́n tó ní agbára. Bíbélì pe Ọlọ́run ní Ẹni Ẹ̀mí Gíga Jù Lọ. Ẹni tó bá sún mọ́ Ọlọ́run máa ń jẹ́ kí ẹ̀mí mímọ́ Ọlọ́run darí òun, ohun tí Ọlọ́run fẹ́ ló sì máa ń ṣe.