Àlàyé Ìsàlẹ̀ Ìwé
c Ọlọ́run fẹ́ kí àwọn tọkọtaya tó ti ṣègbéyàwó jọ máa gbé pọ̀ ní gbogbo ọjọ́ ayé wọn. Àfi ti ọ̀kan lára wọn bá ṣe àgbèrè ni wọ́n fi lè tú ká, kí wọ́n sì fẹ́ ẹlòmíì. (Mátíù 19:9) Tó o bá níṣòro nínú ìdílé ẹ, Bíbélì lè jẹ́ kó o mọ ọ̀nà tó o fi lè fọgbọ́n àti ìfẹ́ yanjú ẹ̀.