Àlàyé Ìsàlẹ̀ Ìwé
b Bíbélì Mímọ́ fi àwọn ọ̀rọ̀ yìí parí Àdúrà Olúwa: “Nitori ijọba ni tirẹ, ati agbara, ati ogo, lailai. Amin.” Àwọn ọ̀rọ̀ tí wọ́n fi yin Ọlọ́run lógo yìí wà nínú àwọn ìtumọ̀ Bíbélì míì. Síbẹ̀, The Jerome Biblical Commentary sọ pé: “Àwọn ọ̀rọ̀ yìí . . . ò sí nínú àwọn Bíbélì àtijọ́ tó ṣeé gbára lé.”