Àlàyé Ìsàlẹ̀ Ìwé
a Ìwé náà The Rise of Christianity tí E. W. Barnes kọ, sọ pé: “Àyẹ̀wò kínníkínní lórí gbogbo ìsọfúnni tó wà lọ́wọ́ fi hàn pé títí di àkókò Marcus Aurelius [tó jẹ́ Olú Ọba Róòmù láti 161 sí 180 Sànmánì Kristẹni] kò sí Kristẹni kankan tó wọṣẹ́ ológun; gbogbo àwọn tó sì jẹ́ ológun tẹ́lẹ̀ ló fiṣẹ́ náà sílẹ̀ lẹ́yìn tí wọ́n di Kristẹni.”