Àlàyé Ìsàlẹ̀ Ìwé
b Àwọn Bíbélì kan lo ọ̀rọ̀ tó túmọ̀ sí “ṣíṣe nǹkan léraléra” nígbà tí wọ́n ń sọ̀rọ̀ nípa Oúnjẹ Alẹ́ Olúwa, bí wọ́n sì ṣe máa ń ṣàlàyé ọ̀rọ̀ yẹn ni pé ó yẹ ká máa ṣe é léraléra. Àmọ́ ohun tí èdè Gíríìkì tí Bíbélì lò nígbà tó ń sọ̀rọ̀ Oúnjẹ Alẹ́ Olúwa yìí túmọ̀ sí ni “nígbàkúùgbà.”—1 Kọ́ríńtì 11:25, 26; Bíbélì Ìròyìn Ayọ̀.