Àlàyé Ìsàlẹ̀ Ìwé
b Nínú Bíbélì, wọ́n sábà máa ń ṣàpèjúwe Ọlọ́run, tí orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Jèhófà pé ó jẹ́ Olùṣọ́ àgùntàn tó láájò. Àwọn tó ń jọ́sìn rẹ̀ dà bí àgùntàn, wọ́n sì gbára lé e pé ó máa dáàbò bo àwọn, á sì tì àwọn lẹ́yìn.—Sáàmù 100:3; Aísáyà 40:10, 11; Jeremáyà 31:10; Ìsíkíẹ́lì 34:11-16.