ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • Ohun Tí Bíbélì Sọ Nípa Ìyè àti Ikú
    Ilé Ìṣọ́ (Ẹ̀dà Tá À Ń Fi Sóde)—2017 | No. 4
    • BÍBÉLÌ JẸ́ KÁ MỌ ÒTÍTỌ́

      Ìtàn nípa ìṣẹ̀dá tó wà nínú ìwé Jẹ́nẹ́sísì sọ pé: “Jèhófà Ọlọ́run sì bẹ̀rẹ̀ sí ṣẹ̀dá ọkùnrin náà láti inú ekuru ilẹ̀, ó sì fẹ́ èémí ìyè sínú ihò imú rẹ̀, ọkùnrin náà sì wá di alààyè ọkàn.” Ọ̀rọ̀ Hébérù tá a túmọ̀ sí “alààyè ọkàn” ni ne’phesh, ó sì tún lè túmọ̀ sí “ẹ̀dá tó ń mí.”—Jẹ́nẹ́sísì 2:7.

      Bíbélì tipa báyìí mú kó ṣe kedere pé Ọlọ́run kò dá ọkàn tí kì í kú mọ́ wa. Kàkà bẹ́ẹ̀, ẹnì kọ̀ọ̀kan wa ni “alààyè ọkàn.” Ìdí nìyẹn tó fi jẹ́ pé kò sí ibì kankan nínú Bíbélì tó o ti lè rí ọ̀rọ̀ tó fi hàn pé ọkàn kì í kú.

  • Ohun Tí Bíbélì Sọ Nípa Ìyè àti Ikú
    Ilé Ìṣọ́ (Ẹ̀dà Tá À Ń Fi Sóde)—2017 | No. 4
    • Kò sí ibì kankan nínú Bíbélì tó o ti lè rí ọ̀rọ̀ tó fi hàn pé ọkàn kì í kú

Yorùbá Publications (1987-2025)
Jáde
Wọlé
  • Yorùbá
  • Fi Ráńṣẹ́
  • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
  • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
  • Àdéhùn Nípa Lílò
  • Òfin
  • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
  • JW.ORG
  • Wọlé
Fi Ráńṣẹ́