-
Àpẹẹrẹ Ìfara-Ẹni-Rúbọ àti ÌdúróṣinṣinIlé Ìṣọ́—1997 | November 1
-
-
Nígbà tí a nawọ́ ìkésíni láti ṣe iṣẹ́ ìsìn àkànṣe pẹ̀lú Èlíjà sí i, ojú ẹsẹ̀ ni Èlíṣà fi pápá rẹ̀ sílẹ̀ láti ṣe ìránṣẹ́ fún wòlíì títayọ jù lọ ní Ísírẹ́lì. Ó hàn kedere pé, díẹ̀ nínú iṣẹ́ rẹ̀ kò fi bẹ́ẹ̀ jọjú, nítorí a mọ̀ ọ́n sì ẹni tí ó “ń tú omi sí ọwọ́ Èlíjà.”c (Àwọn Ọba Kejì 3:11) Síbẹ̀síbẹ̀, Èlíṣà wo iṣẹ́ rẹ̀ gẹ́gẹ́ bí àǹfààní kan, ó sì fi ìdúróṣinṣin dúró ti Èlíjà gbágbágbá.
-
-
Àpẹẹrẹ Ìfara-Ẹni-Rúbọ àti ÌdúróṣinṣinIlé Ìṣọ́—1997 | November 1
-
-
c Ó jẹ́ àṣà fún ìránṣẹ́ kan láti tú omi sí ọ̀gá rẹ̀ lọ́wọ́, kí ó lè fi fọ̀ ọwọ́, ní pàtàkì, lẹ́yìn oúnjẹ. Àṣà yí fara jọ ti wíwẹ ẹsẹ̀, tí ó jẹ́ ìwà aájò àlejò, ọ̀wọ̀, àti ní ọ̀pọ̀ àyíká ipò, ó jẹ́ ìrẹ̀lẹ̀.—Jẹ́nẹ́sísì 24:31, 32; Jòhánù 13:5.
-