ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • Ní Ọgbọ́n, Kí O Sì Gba Ìbáwí
    Ilé Ìṣọ́—1999 | September 15
    • Àwọn ọ̀dọ́ ni ọlọgbọ́n ọba náà tún bá sọ̀rọ̀, ó ní: “Fetí sílẹ̀, ọmọ mi, sí ìbáwí baba rẹ, má sì ṣá òfin ìyá rẹ tì. Nítorí ọ̀ṣọ́ òdòdó fífanimọ́ra ni wọ́n jẹ́ fún orí rẹ àti àtàtà ìlẹ̀kẹ̀ ọrùn fún ọrùn rẹ.”—Òwe 1:8, 9.

  • Ní Ọgbọ́n, Kí O Sì Gba Ìbáwí
    Ilé Ìṣọ́—1999 | September 15
    • Lóòótọ́, jálẹ̀ inú Bíbélì, ìdílé jẹ́ ẹ̀ka pàtàkì táa ti ń fi ẹ̀kọ́ kọ́ni. (Éfésù 6:1-3) Bí àwọn ọmọ bá ṣègbọràn sí àwọn òbí wọn onígbàgbọ́ ṣe ni yóò dà bíi pé a gbé òdodo tó fani mọ́ra kọ́ wọn lọ́rùn, tí a sì tún wá fi ìlẹ̀kẹ̀ ọlá sí i.

Yorùbá Publications (1987-2025)
Jáde
Wọlé
  • Yorùbá
  • Fi Ráńṣẹ́
  • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
  • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
  • Àdéhùn Nípa Lílò
  • Òfin
  • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
  • JW.ORG
  • Wọlé
Fi Ráńṣẹ́