-
Jèhófà JọbaÀsọtẹ́lẹ̀ Aísáyà—Ìmọ́lẹ̀ fún Gbogbo Aráyé, Apá Kìíní
-
-
18, 19. (a) Kí ló ṣeé ṣe kí “ẹgbẹ́ ọmọ ogun ibi gíga” tọ́ka sí, báwo ni wọ́n sì ṣe kó wọn jọ sí “inú àjà ilẹ̀”? (b) Báwo ló ṣe jọ pé wọ́n máa yí àfiyèsí sí “ẹgbẹ́ ọmọ ogun ibi gíga” lẹ́yìn “ọjọ́ púpọ̀ yanturu”? (d) Báwo ni Jèhófà ṣe yí àfiyèsí sí “àwọn ọba lórí ilẹ̀”?
18 Wàyí o, àsọtẹ́lẹ̀ Aísáyà wá rìn jìnnà kọjá ọ̀ràn àwọn ará Júdà, ó wá sọ nípa bí ète Jèhófà yóò ṣe ṣẹ ní paríparì rẹ̀, ó ní: “Yóò sì ṣẹlẹ̀ ní ọjọ́ yẹn pé Jèhófà yóò yí àfiyèsí rẹ̀ sí ẹgbẹ́ ọmọ ogun ibi gíga ní ibi gíga, àti sí àwọn ọba ilẹ̀ lórí ilẹ̀. Ṣe ni a ó fi ìkójọ bí ti àwọn ẹlẹ́wọ̀n kó wọn jọ sínú kòtò, a ó sì tì wọ́n pa mọ́ inú àjà ilẹ̀; a ó sì fún wọn ní àfiyèsí lẹ́yìn ọjọ́ púpọ̀ yanturu. Òṣùpá àrànmọ́jú sì ti tẹ́, ìtìjú sì ti bá oòrùn tí ń ràn yòò, nítorí pé Jèhófà àwọn ẹgbẹ́ ọmọ ogun ti di ọba tògo-tògo ní Òkè Ńlá Síónì àti ní Jerúsálẹ́mù àti ní iwájú àwọn àgbàlagbà ọkùnrin rẹ̀.”—Aísáyà 24:21-23.
-
-
Jèhófà JọbaÀsọtẹ́lẹ̀ Aísáyà—Ìmọ́lẹ̀ fún Gbogbo Aráyé, Apá Kìíní
-
-
[Àwòrán tó wà ní ojú ìwé 269]
Ògo òṣùpá tàbí ti oòrùn kò ní tó ògo Jèhófà
-