-
Àpèjúwe Àwọn Òṣìṣẹ́ Ọgbà ÀjàràJésù—Ọ̀nà, Òtítọ́ Àti Ìyè
-
-
“Ìjọba ọ̀run dà bíi baálé ilé kan tó jáde lọ ní àárọ̀ kùtù láti gba àwọn òṣìṣẹ́ sínú ọgbà àjàrà rẹ̀. Lẹ́yìn tó bá àwọn òṣìṣẹ́ náà ṣàdéhùn pé òun máa fún wọn ní owó dínárì kan fún ọjọ́ kan, ó ní kí wọ́n lọ sínú ọgbà àjàrà òun. Ó tún jáde ní nǹkan bíi wákàtí kẹta, ó sì rí àwọn míì tí wọ́n dúró ní ibi ọjà, tí wọn ò ríṣẹ́ ṣe; ó sọ fún wọn pé, ‘Ẹ̀yin náà, ẹ lọ sínú ọgbà àjàrà, màá sì fún yín ní ohunkóhun tó bá tọ́.’ Torí náà, wọ́n lọ. Ó tún jáde ní nǹkan bíi wákàtí kẹfà àti wákàtí kẹsàn-án, ó sì ṣe ohun kan náà. Níkẹyìn, ní nǹkan bíi wákàtí kọkànlá, ó jáde lọ, ó sì rí àwọn míì tí wọ́n dúró, ó sọ fún wọn pé, ‘Kí ló dé tí ẹ dúró síbí látàárọ̀, tí ẹ ò ríṣẹ́ ṣe?’ Wọ́n sọ fún un pé, ‘Torí kò sẹ́ni tó gbà wá síṣẹ́ ni.’ Ó sọ fún wọn pé, ‘Ẹ̀yin náà, ẹ lọ sínú ọgbà àjàrà.’”—Mátíù 20:1-7.
-
-
Àpèjúwe Àwọn Òṣìṣẹ́ Ọgbà ÀjàràJésù—Ọ̀nà, Òtítọ́ Àti Ìyè
-
-
“Ìjọba ọ̀run dà bíi baálé ilé kan tó jáde lọ ní àárọ̀ kùtù láti gba àwọn òṣìṣẹ́ sínú ọgbà àjàrà rẹ̀. Lẹ́yìn tó bá àwọn òṣìṣẹ́ náà ṣàdéhùn pé òun máa fún wọn ní owó dínárì kan fún ọjọ́ kan, ó ní kí wọ́n lọ sínú ọgbà àjàrà òun. Ó tún jáde ní nǹkan bíi wákàtí kẹta, ó sì rí àwọn míì tí wọ́n dúró ní ibi ọjà, tí wọn ò ríṣẹ́ ṣe; ó sọ fún wọn pé, ‘Ẹ̀yin náà, ẹ lọ sínú ọgbà àjàrà, màá sì fún yín ní ohunkóhun tó bá tọ́.’ Torí náà, wọ́n lọ. Ó tún jáde ní nǹkan bíi wákàtí kẹfà àti wákàtí kẹsàn-án, ó sì ṣe ohun kan náà. Níkẹyìn, ní nǹkan bíi wákàtí kọkànlá, ó jáde lọ, ó sì rí àwọn míì tí wọ́n dúró, ó sọ fún wọn pé, ‘Kí ló dé tí ẹ dúró síbí látàárọ̀, tí ẹ ò ríṣẹ́ ṣe?’ Wọ́n sọ fún un pé, ‘Torí kò sẹ́ni tó gbà wá síṣẹ́ ni.’ Ó sọ fún wọn pé, ‘Ẹ̀yin náà, ẹ lọ sínú ọgbà àjàrà.’”—Mátíù 20:1-7.
-
-
Àpèjúwe Àwọn Òṣìṣẹ́ Ọgbà ÀjàràJésù—Ọ̀nà, Òtítọ́ Àti Ìyè
-
-
Àwọn aṣáájú ẹ̀sìn Júù gbà pé àwọn ń ṣiṣẹ́ fún Ọlọ́run láìdáwọ́ dúró, irú bí àwọn Farisí tó wá dán Jésù wò láìpẹ́ sígbà yẹn lórí ọ̀rọ̀ ìkọ̀sílẹ̀. Àwọn ló dà bí àwọn òṣìṣẹ́ tó ṣiṣẹ́ látàárọ̀ ṣúlẹ̀ tí wọ́n sì ń retí àtigba dínárì kan tó jẹ́ owó táwọn òṣìṣẹ́ máa ń gbà lójúmọ́.
-