ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • Ǹjẹ́ O Mọ̀?
    Ilé Ìṣọ́—2011 | October 1
    • ▪ Nígbà tó kù díẹ̀ kí Jésù kú, ó sọ̀rọ̀ nípa ìwà ìrẹ́jẹ tó bùáyà tó ń ṣẹlẹ̀ nínú tẹ́ńpìlì. Bíbélì ròyìn pé: “Jésù . . . lé gbogbo àwọn tí ń tà, tí wọ́n sì ń rà nínú tẹ́ńpìlì síta, ó sì sojú tábìlì àwọn olùpààrọ̀ owó dé àti bẹ́ǹṣì àwọn tí ń ta àdàbà. Ó sì wí fún wọn pé: “A ti kọ̀wé rẹ̀ pé, ‘Ilé mi ni a óò máa pè ní ilé àdúrà,’ ṣùgbọ́n ẹ ń sọ ọ́ di hòrò àwọn ọlọ́ṣà.’”—Mátíù 21:12, 13.

  • Ǹjẹ́ O Mọ̀?
    Ilé Ìṣọ́—2011 | October 1
    • Bí Jésù ṣe bá àwọn tó ń pààrọ̀ owó wí pé wọ́n ti sọ tẹ́ńpìlì di “hòrò àwọn ọlọ́ṣà” fi hàn kedere pé iye tí wọ́n ń gbà lọ́wọ́ àwọn tó fẹ́ pààrọ̀ owó ti pọ̀ jù.

Yorùbá Publications (1987-2025)
Jáde
Wọlé
  • Yorùbá
  • Fi Ráńṣẹ́
  • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
  • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
  • Àdéhùn Nípa Lílò
  • Òfin
  • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
  • JW.ORG
  • Wọlé
Fi Ráńṣẹ́