-
“Ẹ Lọ, Kí Ẹ sì Máa Sọ Àwọn Ènìyàn . . . Di Ọmọ Ẹ̀yìn”“Máa Tọ̀ Mí Lẹ́yìn”
-
-
11 Jésù kọ́ àwọn ọmọlẹ́yìn rẹ̀ láti gbẹ́kẹ̀ lé Jèhófà. Ó sọ fún wọn pé: “Ẹ má ṣe wá wúrà tàbí fàdákà tàbí bàbà sínú àpò ara àmùrè yín, tàbí àsùnwọ̀n oúnjẹ fún ìrìnnà àjò náà, tàbí ẹ̀wù àwọ̀tẹ́lẹ̀ méjì, tàbí sálúbàtà tàbí ọ̀pá; nítorí òṣìṣẹ́ yẹ fún oúnjẹ rẹ̀.” (Mátíù 10:9, 10) Ohun tó wọ́pọ̀ nígbà yẹn ni pé kẹ́ni tó bá máa rìnrìn àjò de àmùrè tó ní àpò tí wọ́n máa fi owó sí, kó gbé àsùnwọ̀n oúnjẹ kó sì mú sálúbàtà míì yàtọ̀ sí èyí tó wọ̀ sí ẹsẹ̀ dání.a Nípa fífún wọn nítọ̀ọ́ni pé kí wọ́n má ṣàníyàn nípa àwọn nǹkan yẹn, Jésù ń tipa báyẹn sọ fún wọn pé: “Ẹ gbé ẹkẹ̀ yín lé Jèhófà pátápátá, torí pé ó máa pèsè ohun tẹ́ ẹ bá nílò fún yín.” Jèhófà á pèsè fún wọn ní ti pé á mú kí àwọn tó bá gbọ́ ìhìn rere ṣe wọ́n lálejò, èyí tó jẹ́ àṣà wọn ní Ísírẹ́lì.—Lúùkù 22:35.
-
-
“Ẹ Lọ, Kí Ẹ sì Máa Sọ Àwọn Ènìyàn . . . Di Ọmọ Ẹ̀yìn”“Máa Tọ̀ Mí Lẹ́yìn”
-
-
11 Jésù kọ́ àwọn ọmọlẹ́yìn rẹ̀ láti gbẹ́kẹ̀ lé Jèhófà. Ó sọ fún wọn pé: “Ẹ má ṣe wá wúrà tàbí fàdákà tàbí bàbà sínú àpò ara àmùrè yín, tàbí àsùnwọ̀n oúnjẹ fún ìrìnnà àjò náà, tàbí ẹ̀wù àwọ̀tẹ́lẹ̀ méjì, tàbí sálúbàtà tàbí ọ̀pá; nítorí òṣìṣẹ́ yẹ fún oúnjẹ rẹ̀.” (Mátíù 10:9, 10) Ohun tó wọ́pọ̀ nígbà yẹn ni pé kẹ́ni tó bá máa rìnrìn àjò de àmùrè tó ní àpò tí wọ́n máa fi owó sí, kó gbé àsùnwọ̀n oúnjẹ kó sì mú sálúbàtà míì yàtọ̀ sí èyí tó wọ̀ sí ẹsẹ̀ dání.a Nípa fífún wọn nítọ̀ọ́ni pé kí wọ́n má ṣàníyàn nípa àwọn nǹkan yẹn, Jésù ń tipa báyẹn sọ fún wọn pé: “Ẹ gbé ẹkẹ̀ yín lé Jèhófà pátápátá, torí pé ó máa pèsè ohun tẹ́ ẹ bá nílò fún yín.” Jèhófà á pèsè fún wọn ní ti pé á mú kí àwọn tó bá gbọ́ ìhìn rere ṣe wọ́n lálejò, èyí tó jẹ́ àṣà wọn ní Ísírẹ́lì.—Lúùkù 22:35.
-
-
“Ẹ Lọ, Kí Ẹ sì Máa Sọ Àwọn Ènìyàn . . . Di Ọmọ Ẹ̀yìn”“Máa Tọ̀ Mí Lẹ́yìn”
-
-
a Ó ṣeé ṣe kí àpò ara àmùrè jẹ́ oríṣi àpò kan tó máa ń wà lára ìgbànú tó wà fún kíkó owó ẹyọ sí. Àsùnwọ̀n oúnjẹ máa ń tóbi díẹ̀, awọ ni wọ́n sì sábà máa ń fi ṣe é, wọ́n máa ń gbé e kọ́ èjìká, inú rẹ̀ ni wọ́n máa ń kó oúnjẹ tàbí àwọn èlò mìíràn sí.
-