ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • w08 12/15 ojú ìwé 31
  • Atọ́ka Àwọn Àkòrí Ilé Ìṣọ́ Ọdún 2008

Kò sí fídíò kankan ní apá yìí.

Má bínú, fídíò yìí kò jáde.

  • Atọ́ka Àwọn Àkòrí Ilé Ìṣọ́ Ọdún 2008
  • Ilé Ìṣọ́ Tí Ń Kéde Ìjọba Jehofa—2008
  • Ìsọ̀rí
  • ÀWỌN ÀPILẸ̀KỌ FÚN ÌKẸ́KỌ̀Ọ́
  • ÀWỌN ẸLẸ́RÌÍ JÈHÓFÀ
  • BÍBÉLÌ
  • ÌGBÉSÍ AYÉ ÀTÀWỌN ÀNÍMỌ́ KRISTẸNI
  • ÌTÀN ÌGBÉSÍ AYÉ
  • JÈHÓFÀ
  • JÉSÙ KRISTI
  • Ọ̀KÀN-Ò-JỌ̀KAN
Ilé Ìṣọ́ Tí Ń Kéde Ìjọba Jehofa—2008
w08 12/15 ojú ìwé 31

Atọ́ka Àwọn Àkòrí Ilé Ìṣọ́ Ọdún 2008

Tó ń tọ́ka sáwọn ìtẹ̀jáde Ilé Ìṣọ́ táwọn àpilẹ̀kọ kan ti jáde

ÀWỌN ÀPILẸ̀KỌ FÚN ÌKẸ́KỌ̀Ọ́

Àwọn Ànímọ́ Tá A Gbọ́dọ̀ Máa Lépa, 6/15

Àwọn Ohun Tá A Gbọ́dọ̀ Máa Sá Fún, 6/15

Àwọn Tó “Ní Ìtẹ̀sí-Ọkàn Títọ́” Ń Kọbi Ara sí Ìwàásù Wa, 1/15

Bá A Ṣe Lè Borí Ìṣòro Lẹ́nu Iṣẹ́ Ìwàásù Ilé-dé-Ilé, 7/15

Bá A Ṣe Lè Mọyì Ipa Tó Ṣàrà Ọ̀tọ̀ Tí Jésù Kó Nínú Mímú Àwọn Ohun Tí Ọlọ́run Ní Lọ́kàn Ṣẹ, 12/15

Báwo Lèèyàn Ṣe Lè Gbé Ìgbé Ayé Rere? 4/15

Báwo Ló Ṣe Yẹ Ká Máa Ṣe Sáwọn Èèyàn? 5/15

“Ẹ Kọ Ojú Ìjà sí Èṣù” Bí Jésù Ti Ṣe, 11/15

Ẹ Máa Ṣe Rere, 5/15

Ẹ Máa Tẹ̀ Lé Ìlànà Ìwé Mímọ́ Lórí Ọ̀rọ̀ Ìtọ́jú Ara, 11/15

Ẹ Ràn Wọ́n Lọ́wọ́ Kí Wọ́n Lè Pa Dà Sínú Agbo, 11/15

Ẹ Ràn Wọ́n Lọ́wọ́ Kí Wọ́n Lè Tètè Pa Dà! 11/15

Ẹ̀yin Ọ̀dọ́, Ẹ Rántí Ẹlẹ́dàá Yín Atóbilọ́lá Nísinsìnyí, 4/15

Fiyè sí “Ọnà Ìkọ́nilẹ́kọ̀ọ́” Rẹ, 1/15

Ìdáǹdè Nípasẹ̀ Ìjọba Ọlọ́run Kù sí Dẹ̀dẹ̀! 5/15

Ìdí Tó Fi Yẹ Kó O Pa Ìwà Títọ́ Rẹ Mọ́, 12/15

Ìgbéyàwó àti Ọmọ Bíbí Lákòókò Òpin Yìí, 4/15

Ìwọ Kò Mọ Ibi Tí Yóò Ti Ṣàṣeyọrí! 7/15

Jèhófà Dáhùn Àdúrà Àtọkànwá Tí Ìránṣẹ́ Rẹ̀ Kan Gbà, 10/15

Jèhófà Jẹ́ “Olùpèsè Àsálà” fún Wa, 9/15

Jèhófà Jẹ́ “Olùpèsè Àsálà” Láyé Ìgbà Tí Wọ́n Ń Kọ Bíbélì, 9/15

Jèhófà Kì Yóò Fi Àwọn Ẹni Ìdúróṣinṣin Rẹ̀ Sílẹ̀, 8/15

Jèhófà Ń Gbọ́ Igbe Wa Fún Ìrànlọ́wọ́, 3/15

Jèhófà Ń Ṣìkẹ́ Àwọn Ìránṣẹ́ Rẹ̀ Tó Jẹ́ Àgbàlagbà, 8/15

Jèhófà Ń Ṣọ́ Wa Fún Ire Wa, 10/15

Jésù Kristi—Míṣọ́nnárì Tó Ta Yọ, 2/15

Jẹ́ Kí Ayọ̀ Wà Nínú Ilé Rẹ, 3/15

Jẹ́ Kí Jèhófà Wà Níwájú Rẹ Nígbà Gbogbo, 2/15

Jẹ́ Kí Ọlọ́run Máa Ṣamọ̀nà Rẹ Nínú Ohun Gbogbo, 4/15

Kí Lo Máa Yááfì Kó O Lè Ní Ìyè Àìnípẹ̀kun? 10/15

Kí Nìdí Tí Iṣẹ́ Ìwàásù Ilé-dé-Ilé Fi Ṣe Pàtàkì Nísinsìnyí? 7/15

Kọ “Àwọn Ohun Tí Kò Ní Láárí” Sílẹ̀, 4/15

Máa Jẹ́ Adúróṣinṣin Pẹ̀lú Ọkàn Tó Ṣọ̀kan, 8/15

Máa Jẹ́ Kí Ìgbéyàwó Rẹ Jẹ́ “Okùn Onífọ́nrán Mẹ́ta,” 9/15

Máa Rìn ní Ọ̀nà Jèhófà, 2/15

Máa Ṣe Ohun Tó Ń Gbé Iyì Jèhófà Yọ, 8/15

Máa Ṣọ́ Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Tí O Tẹ́wọ́ Gbà Nínú Olúwa,” 1/15

Máa Tẹ̀ Lé Àṣẹ Jèhófà, 6/15

Má Ṣe Fàyè Gba “Ẹ̀mí Ayé,” 9/15

Má Ṣe Jẹ́ Kí ‘Ìfẹ́ Tó O Ní Lákọ̀ọ́kọ́’ Jó Rẹ̀yìn, 6/15

Má Ṣe Máa Rin Kinkin, 3/15

Ǹjẹ́ Ò Ń Sọ “Èdè Mímọ́” Lọ́nà Tó Já Geere? 8/15

Ojú Jèhófà “Títàn Yanran” Ń Ṣàyẹ̀wò Gbogbo Èèyàn, 10/15

Ọlọ́run Kà Wá Yẹ Láti Gba Ìjọba Kan, 1/15

Ọlọ́run Kà Wọ́n Sẹ́ni Tó Yẹ Láti Ṣamọ̀nà Lọ Sáwọn Ìsun Omi Ìyè, 1/15

‘Ọlọ́run Ló Ń Mú Kí Ó Dàgbà’! 7/15

Pinnu Láti Sin Jèhófà Látìgbà Èwe Rẹ, 5/15

Ṣé O Ń Mú Ipò Iwájú Nínú Bíbu Ọlá Fáwọn Èèyàn? 10/15

Ṣé Ojú Tí Jèhófà Fi Ń Wo Àwọn Èèyàn Lo Fi Ń Wò Wọ́n? 3/15

Ṣé Wàá Pa Ìwà Títọ́ Rẹ Mọ́? 12/15

“Ta Ni Nínú Yín Tí Ó Jẹ́ Ọlọ́gbọ́n àti Olóye?” 3/15

Tẹ̀ Lé Àpẹẹrẹ Míṣọ́nnárì Tó Ta Yọ, 2/15

Tẹ̀ Lé Àpẹẹrẹ Pọ́ọ̀lù Kó O Lè Tẹ̀ Síwájú Nínú Òtítọ́, 5/15

Wọ́n Pinnu Láti Jẹ́rìí Kúnnákúnná sí Ìhìn Rere, 12/15

Wíwàníhìn-ín Kristi—Báwo Ló Ṣe Yé Ọ Sí? 2/15

ÀWỌN ẸLẸ́RÌÍ JÈHÓFÀ

Àdéhùn Pàtàkì Kan, 3/15

Àjálù Ṣẹlẹ̀ Ní Erékùṣù Solomon Islands, 5/1

Àwọn Maya Rí Òmìnira Tòótọ́ Gbà, 12/1

Bá A Ṣe Mú Ìhìn Rere Dé ilẹ̀ Bòlífíà, 3/15

Bí A Ṣe Ṣètò Ìgbìmọ̀ Olùdarí, 5/15

Bíbélì Máa Ń Sọni Dèèyàn Rere, 8/1

Gbogbo Wọn Ń Fi “Ọkàn Kan” Sin Ọlọ́run (àwọn ọrẹ), 11/15

Ìdí Tí Wọ́n Fi Pe Tonílé Tàlejò (Orílẹ̀-èdè South Africa), 11/1

Ìkẹ́kọ̀ọ́yege ní Gílíádì, 2/15, 8/15

Ilé Ìṣọ́ Ẹ̀dà Tuntun Tó Wà fún Ìkẹ́kọ̀ọ́, 1/15

Ilé Tó Ń Fìyìn Fún Jèhófà (Gbọ̀ngàn Ìjọba ní Mẹ́síkò, Belize), 2/1

Iṣẹ́ Ìwàásù àti Ìkọ́nilẹ́kọ̀ọ́ Nílẹ̀ Áfíríkà, 3/1

Kí Nìdí Tí Wọn Kì Í Fi Í Lo Àgbélébùú? 3/1

Kí Nìdí Tí Wọn Ki Í Fi Í Lọ Sójú Ogun? 7/1

‘Màá Kà Á Létí Iná Àgọ́,’ 6/1

“Mi Ò Rí Irú Ìfẹ́ Báyìí Rí” (Ilẹ̀ Dominican Republic), 3/1

Mo Rí I Bí Ẹ̀mí Wa Ti Ṣeyebíye Tó, 9/1

Ó Múra Tán Láti Gbèjà Ìgbàgbọ́ (ọ̀dọ́mọbìnrin ọmọléèwé), 6/15

Ọgbọ́n Táwọn Kan Dá (láti lọ sí àpéjọ àgbègbè), 6/15

Ọjọ́ Tí Akọni Dèèyàn Jẹ́jẹ́, 12/1

Ọmọbìnrin Tó Ṣe Bí Ọmọdébìnrin Ilẹ̀ Ísírẹ́lì Àtijọ́, 6/1

Sí Ẹ̀yin Òǹkàwé Wa (àwọn nǹkan tuntun nínú Ilé Ìṣọ́), 1/1

Ṣáwọn Nìkan Ló Máa Nígbàlà? 11/1

Ṣé Wọ́n Gba Májẹ̀mú Láéláé Gbọ́? 12/1

Ṣé Wọn Máa Ń Tú Ìgbéyàwó Ká Ni? 11/1

“Tó O Bá Dé Etí Odò Coco, Yà Sápá Ọ̀tún,” 9/1

Wíwàásù ní Ọjà, 9/15

Wọ́n Gbèjà Àwọn Tí Wọ́n Hùwà Ìkà Sí (lórílẹ̀-èdè Georgia), 3/1

BÍBÉLÌ

Àwọn Kókó Pàtàkì Látinú Ìwé Gálátíà, Éfésù, Fílípì àti Kólósè, 8/15

Àwọn Kókó Pàtàkì Látinú Ìwé Ìṣe, 5/15

Àwọn Kókó Pàtàkì Látinú Ìwé Jákọ́bù, Pétérù Kìíní àti Pétérù Kejì, 11/15

Àwọn Kókó Pàtàkì Látinú Ìwé Jòhánù, 4/15

Àwọn Kókó Pàtàkì Látinú Ìwé Jòhánù Kìíní, Jòhánù Kejì, Jòhánù Kẹta àti Ìwé Júúdà, 12/15

Àwọn Kókó Pàtàkì Látinú Ìwé Kọ́ríńtì Kìíní àti Ìkejì, 7/15

Àwọn Kókó Pàtàkì Látinú Ìwé Lúùkù, 3/15

Àwọn Kókó Pàtàkì Látinú Ìwé Máàkù, 2/15

Àwọn Kókó Pàtàkì Látinú Ìwé Mátíù, 1/15

Àwọn Kókó Pàtàkì Látinú Ìwé Róòmù, 6/15

Àwọn Kókó Pàtàkì Látinú Ìwé Tẹsalóníkà Kìíní àti Ìkejì, àti Ìwé Tímótì Kìíní àti Ìkejì, 9/15

Àwọn Kókó Pàtàkì Látinú Ìwé Títù, Fílémónì, àti Hébérù, 10/15

Bíbélì Máa Ń Sọni Dèèyàn Rere, 8/1

“Ìwé Orin Òkun,” 11/15

Mọ Bíbélì Tí Wọ́n Túmọ̀ Lọ́nà Tó Dára, 5/1

Ohun Tí Jésù Sọ Ni Wọ́n Kọ Sínú Ìwé Mímọ́, 9/1

Ṣé Bíbélì Sọ Bọ́jọ́ Ọ̀la Ṣe Máa Rí? 10/1

Ṣóòótọ́ Làwọn Ọ̀rọ̀ Inú Àwọn Ìwé Ìhìn Rere? 10/1

Wàláà Ayé Àtijọ́ àti Bíbélì, 12/15

ÌGBÉSÍ AYÉ ÀTÀWỌN ÀNÍMỌ́ KRISTẸNI

A Lè Jẹ́ Alágbára Láìfi Àìlera Wa Pè, 6/15

Bá A Ṣe Lè Bá Àwọn Ọmọ Tó Ṣẹ̀ṣẹ̀ Ń Bàlágà Sọ̀rọ̀, 8/1

Bá A Ṣe Lè Yanjú Èdèkòyedè (nínú ìgbéyàwó), 2/1

Bá A Ṣe Lè Yanjú Ìṣòro, 5/1

Béèyàn Ṣe Lè Jẹ́ Bàbá Rere, 10/1

Bí A Ṣe Lè Tu Aláìsàn Tó Ń Retí Ikú Nínú, 5/1

Bí Tọkọtaya Ṣe Lè Máa Ṣera Wọn Lọ́kan, 11/1

Bó Ṣe Yẹ Ká Máa Hùwà Sáwọn Èèyàn, 8/1

“Ẹ Di Aláfarawé Ọlọ́run,” 10/1

Ẹ Máa Wà Ní Mímọ́ Nínú Ìbẹ̀rù Ọlọ́run, 5/15

Ẹ̀mí Ìtọpinpin, 6/1

Fi Àṣìṣe Àwọn Ọmọ Ísírẹ́lì Kọ́gbọ́n, 2/15

Iṣẹ́ Tó Lè Fún Abiyamọ Nítẹ̀ẹ́lọ́rùn Jù Lọ, 2/1

Irú Èèyàn Wo Lo Fẹ́ Jẹ́? 11/15

Kí Nìdí Tí Ìmọ́tótó Fi Ṣe Pàtàkì? 12/1

Kí Nìdí Tó Fi Yẹ Ká Máa Dúpẹ́ Oore? 8/1

Máa Fi ‘Ọ̀rọ̀ Tó Dára’ Gbé Ìdílé Rẹ Ró, 1/1

Máa Kún Fún Ìmọ̀ Pípéye, 9/15

“Máa Lépa Àwọn Ohun Tí Ń Yọrí sí Àlàáfíà,” 11/15

Máa Ro Ìgbẹ̀yìn Ọ̀rọ̀, 9/1

Nígbà Tí Èṣù Bá Ku Àwọn Kristẹni bí Àlìkámà, 1/15

O Ṣì Lè Láyọ̀ Bí O Tilẹ̀ Rí Ìjákulẹ̀, 3/1

Ohun Tọ́wọ́ Rẹ Lè Tẹ̀ Ni Kó O Fi Ṣe Àfojúsùn Rẹ, 7/15

Ọmọ Títọ́ Láyé Táwọn Èèyàn Ti Ń Ṣèyí Tó Wù Wọ́n, 4/1

Ọmọbìnrin Kan Ran Ọ̀gá Rẹ̀ Lọ́wọ́, 6/1

Ran Ọmọ Rẹ Lọ́wọ́ Kó Lè Borí Ẹ̀dùn Ọkàn Tí Ikú Fà, 7/1

Sámúẹ́lì Tẹra Mọ́ Ṣíṣe Ohun Tí Ó Tọ́, 8/1

Ṣé Ohun Tó Ò Ń Gbèrò Kò Ta Ko Ìfẹ́ Ọlọ́run? 7/1

Ṣé Orí Àpáta Lò Ń Kọ́lé sí àbí Orí Iyanrìn? 11/1

Ṣó O Máa Ń Jowú? Òjòwú Làwọn Ẹ̀gbọ́n Jósẹ́fù, 10/1

Tẹ̀ Lé Àpẹẹrẹ Jésù—Sin Ọlọ́run bí Ọlọ́run Ṣe Fẹ́, 9/15

Wọn Ò Sí Láàárín Wa àmọ́ A Kò Gbàgbé Wọn (ilé ìtọ́jú arúgbó), 4/15

Wọ́n Yan Ohun Tó Sàn Jù, 1/15

ÌTÀN ÌGBÉSÍ AYÉ

Àṣìṣe Wọn Ni Mò Ń Wá Ni Mo Bá Rí Òtítọ́ (R. S. Marshall), 12/1

Àyà Ò Fò Wá Torí Jèhófà Wà Pẹ̀lú Wa (E. Petridou), 7/15

Ayọ̀ Mi Ò Lópin Bí Mo Ti Ń Ṣe Ìfẹ́ Ọlọ́run (B. Yaremchuk), 6/1

Bí Ìgbàgbọ́ Mi Ṣe Ràn mí Lọ́wọ́ Láti Fara Da Ìṣòro (S. Castillo), 10/1

“Jèhófà Ni Okun Mi” (J. Coville), 10/15

“Má Ṣe Gbàgbé Iṣẹ́ Ìwáàsú Ilé-dé-Ilé” (J. Neufeld), 9/1

Mo Bọ́ Lọ́wọ́ Ìdààmú Ìgbà Ọ̀dọ́ (E. Morcillo), 1/1

Mo Ti Rí Báwọn Èèyàn Ọlọ́run Ṣe Pọ̀ Sí I Lórílẹ̀-Èdè Kòríà (M. Hamilton), 12/15

“Ó Ń Ṣamọ̀nà Mi Ní Àwọn Òpó Ọ̀nà Òdodo” (O. Campbell), 3/1

Ọlọ́run Fi Àánú Hàn sí Mi (B. Močnik), 7/1

JÈHÓFÀ

Àsọtẹ́lẹ̀ Jèhófà Máa Ń Ṣẹ, 1/1

Bó O Ṣe Lè Di Ọmọ Ọlọ́run, 3/1

“Ẹ Di Aláfarawé Ọlọ́run,” 10/1

Ẹlẹ́dàá Tó Yẹ Ká Fọpẹ́ Fún, 12/1

Ẹni Tó Máa Ń Dárí Jini, 6/1

Ẹni Tó Mọ Ìnira Wa, 5/1

Ẹni Tó Mọyì Wa, 4/1

Ẹni Tó Ń Sọ Òkú Di Alààyè, 3/1

Ìṣẹ̀dá Ń Fi Ọgbọ́n Ọlọ́run Hàn, 5/1

Kí Nìdí Tí Ọlọ́run Fi Fàyè Gba ìjìyà? 2/1

“Kò Jìnnà sí Ẹnì Kọ̀ọ̀kan Wa,” 7/1

Kò sí Bàbá Tó Dà Bíi Rẹ̀, 1/1

Lo Orúkọ Ọlọ́run Bá Ò Tiẹ̀ Mọ Bí Wọ́n Ṣe Ń Pè É, 9/1

Mọ Bàbá Rẹ Ọ̀run, 9/1

Ǹjẹ́ Ohunkóhun “Lè Yà Wá Kúrò Nínú Ìfẹ́ Ọlọ́run”? 8/1

Ó Fẹ́ràn Ìdájọ́ Òdodo, 11/1

Ohun Tá A Kọ́ Lọ́dọ̀ Jésù, 2/1

Olùṣọ́ Àgùntàn Tó Bìkítà, 2/1

“Orúkọ Ọlọ́run Tó Tóbi Tó Sì Jẹ́ Mímọ́,” 10/15

“Ọlọ́run Ìtùnú Gbogbo,” 9/1

Ṣé Bó Ṣe Wù Wá La Ṣe Lè Sin Ọlọ́run? 6/1

Ṣé Ó Yẹ Kí Orúkọ Náà Jèhófà Wà Nínú Májẹ̀mú Tuntun? 8/1

Ṣé “Orúkọ Tá Ò Gbọ́dọ̀ Pè,” Ni? 6/1

Ṣé Ọlọ́run Ló Ǹ Fa Àwọn Ìjábá? 5/1

Ṣó Dáa Kéèyàn Máa Lo Orúkọ Ọlọ́run? 7/1

JÉSÙ KRISTI

Àrà Tí Jésù Ì Bá Fi Iṣẹ́ Káfíńtà Dá, 12/1Àwọn Àsọtẹ́lẹ̀ Nípa Mèsáyà, 10/1

Àwọn “Oníṣẹ́ Báńkì,” 12/1

Àwọn Tó Ń Gbọ́rọ̀ Rẹ̀ Ṣe Kàyéfì, 9/1

Bí Jésù ṣe la ojú afọ́jú kan díẹ̀díẹ̀, 4/1

Bí Ikú Jésù Ṣe Lè Gbà Ọ́, 3/1

Bó Ṣe Yẹ Ká Máa Hùwà Sáwọn Èèyàn, 8/1

Èdè Tí Jésù Sọ, 8/1

Ìgbà Wo Làwọn Awòràwọ̀ Lọ Sọ́dọ̀ Jésù? 1/1

Ipa Wo Ló Kó Nígbèésí Ayé Ẹ? 12/1

Iṣẹ́ Ìyanu, 5/1

Ṣé Iná Ọ̀run Àpáàdì Ni? (Mk 9:48), 6/15

Ṣé “Ọlọ́run” ni àbí “ọlọ́run kan”? 11/1

Kí Nìdí Tá A Fi Ń Gbàdúrà Lórúkọ Jésù? 2/1

Kí Nìdí Tí Ẹ̀rù Fi Ba Pílátù Nígbà Tí Jésù “Fi Ara Rẹ̀ Ṣe Ọmọ Ọlọ́run”? 6/1

Kí Nìdí Tó Fi Gba Ọgbọ̀n Owó Fàdákà? 9/1

Kí Nìdí Tó Fi Gba Jésù Ní Ọjọ́ Mẹ́rin? 1/1

Pétérù Sẹ́ Jésù, 1/1

Ọ̀KÀN-Ò-JỌ̀KAN

Amágẹ́dọ́nì, 4/1

Àwọn Òkúta Tẹ́ńpìlì, 8/1

“Àwọn Ọkọ̀ Òkun Táṣíṣì,” 11/1

Àwọn Tó Ń Sọ Èdè Gíríìkì Lára Àwọn Tó Bẹ̀rẹ̀ Ìsìn Kristẹni, 12/1

Ayé Ń Móoru, 9/1

Báwo Ló Ṣe Ṣeé Ṣe Fún Ádámù Láti Dẹ́ṣẹ̀? 10/1

Báwo Ni Okun Dídà Ṣe Tóbi Tó? 2/1

Báwo Ni Wúrà Sólómọ́nì Ṣe Pọ̀ Tó? 11/1

Bí Sódómù àti Gòmórà Ṣe Pa Run, 3/1

Ẹ̀gbọ́n Bínú sí Àbúrò (Kéènì), 7/1

Fi “Jẹ Àwọn Ohun Ọlọ́ràá,” (Ne 8:10) àti “Ẹ Kò Gbọ́dọ̀ Jẹ Ọ̀rá Èyíkéyìí” (Le 3:17) Wéra, 12/15

Gbígba Ara Olúwa, 4/1

“Gbígbé Ọwọ́ Léni” Lórí (Heb 6:2), 9/15

Ìbàlẹ̀ Ọkàn, 2/1

Ibo Ni Ogun Amágẹ́dọ́nì Ti Máa Jà? 4/1

Ìdí Tá A Fi Wà Láàyè, 2/1

Ìdí Táwọn Júù Fi Máa Ń Bẹ̀rẹ̀ Sábáàtì Nírọ̀lẹ́, 10/1

Ìdí Tí Dáfídì Ò Fi Bẹ̀rù, 12/1

Ìdí Tí Sekaráyà Fi Sàsọtẹ́lẹ̀ Ìparun Ìlú Tírè Lẹ́yìn Tí Wọ́n Pa Ìlú Náà Run, 6/1

Ìgbà Wo Ni Sọ́ọ̀lù Di Pọ́ọ̀lù? 3/1

Ìgbé Ayé Ìrọ̀rùn, 8/1

Ìjọba Ọlọ́run, 1/1, 5/1

Ìlú Jẹ́ríkò Mélòó Ló Wà? 5/1

Ìrètí Fáwọn Òkú, 11/1

“Ìrìn Ọjọ́ Sábáàtì,” 10/1

“Ìwé Ẹ̀rí Ìkọ̀sílẹ̀,” 9/1

Kíka Àkájọ Ìwé, 4/1

Kí Nìdí Táwọn Júù Ò Fi Sí Lójú Kan Nígbà Tí Jésù Wà Láyé? 11/1

Lìdíà Là Wá Lóye, 4/1

Máàkù Ò Rẹ̀wẹ̀sì, 2/1

Nígbà Tí Èèyàn Ẹni Bá Kú, 7/1

Ǹjẹ́ Ẹ̀kọ́ Ẹfolúṣọ̀n Bá Bíbélì Mu? 1/1

Nóà àti Ìkún-Omi, 6/1

Ó Dé ‘Ìparí Èrò Nínú Ọkàn Rẹ̀’ (Màríà), 10/1

‘Òfin Ti Di Akọ́nilẹ́kọ̀ọ́,’ 3/1

Ó Gbèjà Ìjọsìn Mímọ́ (Èlíjà), 1/1

Omi Tó Ń Tú Yàà Sókè Láti Fúnni Ní Ìyè Àìnípẹ̀kun, 6/1

Omijé Nínú Ìgò Awọ, 10/1

Òróró Onílọ́fínńdà tí Màríà Lò, 5/1

Ó Ṣọ́nà Ó sì Ní Sùúrù (Èlíjà), 4/1

Owó Ẹyọ Méjì Tí Opó Fi Sínú Àpótí, 3/1

Owó Kan Ṣoṣo Ni Jésù àti Pétérù Fi San Owó Orí, 2/1

Ọ̀rọ̀ Bẹ́yìn Yọ! (Dáníẹ́lì), 11/1

Ṣé Ayé Yìí Máa Wà Títí Láé? 8/1

Ṣé Gbogbo Àwọn Júù Pátá Máa Di Kristẹni? (Ro 11:26), 6/15

Ṣé Ilẹ̀ Ayé Máa Pa Run? 4/1

Ṣé Méjìlá Làwọn Ẹ̀yà Ísírẹ́lì Ni Àbí Mẹ́tàlá? 7/1

Ṣé Ògiri Tó Ṣeé Fojú Rí Ni? (Ef 2:11-15), 7/1

Ṣé Ọ̀dọ̀ Ọlọ́run Làwọn ‘Iṣẹ́ Ìyanu’ Òde Òní ti Wá? 12/1

Ṣó Yẹ Kó O Máa Bẹ̀rù Ọ̀run Àpáàdì? 11/1

Teli Árádì, 7/1

Tímótì, 4/1

“Wò Ó! Ẹrúbìnrin Jèhófà!” (Màríà), 7/1

    Yorùbá Publications (1987-2025)
    Jáde
    Wọlé
    • Yorùbá
    • Fi Ráńṣẹ́
    • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
    • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
    • Àdéhùn Nípa Lílò
    • Òfin
    • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
    • JW.ORG
    • Wọlé
    Fi Ráńṣẹ́