4 Kó gbé ọwọ́ rẹ̀ lé orí ẹran náà, ọrẹ rẹ̀ yóò sì ní ìtẹ́wọ́gbà, á sì jẹ́ ètùtù fún un.
5 “‘Lẹ́yìn náà, kí wọ́n pa akọ màlúù náà níwájú Jèhófà, àwọn ọmọ Áárónì, tí wọ́n jẹ́ àlùfáà,+ yóò sì gbé ẹ̀jẹ̀ rẹ̀ wá, wọ́n á wọ́n ọn sí gbogbo ẹ̀gbẹ́ pẹpẹ náà,+ èyí tó wà ní ẹnu ọ̀nà àgọ́ ìpàdé.