-
Nọ́ńbà 23:11Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
-
-
11 Bálákì wá sọ fún Báláámù pé: “Kí lo ṣe sí mi yìí? Mo mú ọ wá kí o lè gégùn-ún fún àwọn ọ̀tá mi, àmọ́ ṣe lo kàn wá ń súre fún wọn.”+
-
-
Nọ́ńbà 23:25Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
-
-
25 Bálákì wá sọ fún Báláámù pé: “Tó ò bá ti lè gégùn-ún kankan fún un, kò tún yẹ kí o máa súre fún un.”
-
-
Nọ́ńbà 24:10Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
-
-
10 Inú wá bí Bálákì sí Báláámù gan-an. Bálákì wá fi ìbínú pàtẹ́wọ́, ó sì sọ fún Báláámù pé: “Torí kí o lè gégùn-ún fún àwọn ọ̀tá mi ni mo ṣe pè ọ́ + wá, àmọ́ ṣe lo kàn ń súre fún wọn lẹ́ẹ̀mẹta yìí.
-