-
Àwọn Onídàájọ́ 8:23Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
-
-
23 Àmọ́ Gídíónì sọ fún wọn pé: “Mi ò ní jọba lé yín lórí, ọmọ mi náà ò sì ní jọba lé yín lórí. Jèhófà ló máa jọba lé yín lórí.”+
-