-
Àwọn Onídàájọ́ 8:23Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
-
-
23 Àmọ́ Gídíónì sọ fún wọn pé: “Mi ò ní jọba lé yín lórí, ọmọ mi náà ò sì ní jọba lé yín lórí. Jèhófà ló máa jọba lé yín lórí.”+
-
-
1 Sámúẹ́lì 8:7Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
-
-
7 Jèhófà sì sọ fún Sámúẹ́lì pé: “Fetí sí gbogbo ohun tí àwọn èèyàn náà sọ fún ọ; nítorí kì í ṣe ìwọ ni wọ́n kọ̀, èmi ni wọ́n kọ̀ ní ọba wọn.+
-