ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • 1 Àwọn Ọba 9:26
    Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
    • 26 Ọba Sólómọ́nì tún ṣe ọ̀wọ́ ọkọ̀ òkun ní Esioni-gébérì,+ tí ó wà lẹ́gbẹ̀ẹ́ Élótì, ní èbúté Òkun Pupa ní ilẹ̀ Édómù.+

  • 2 Kíróníkà 20:35-37
    Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
    • 35 Lẹ́yìn náà, Jèhóṣáfátì ọba Júdà bá Ahasáyà ọba Ísírẹ́lì da nǹkan pọ̀, ẹni tó ń hùwà burúkú.+ 36 Nítorí náà, ó fi í ṣe alábàáṣiṣẹ́ láti máa ṣe àwọn ọkọ̀ òkun tí á máa lọ sí Táṣíṣì,+ wọ́n sì ṣe àwọn ọkọ̀ òkun náà ní Esioni-gébérì. + 37 Àmọ́, Élíésérì ọmọ Dódáfáhù láti Márẹ́ṣà sọ àsọtẹ́lẹ̀ sí Jèhóṣáfátì, ó ní: “Torí pé o bá Ahasáyà da nǹkan pọ̀, Jèhófà yóò pa iṣẹ́ rẹ run.”+ Nítorí náà, àwọn ọkọ̀ òkun náà fọ́,+ wọn kò sì lè lọ sí Táṣíṣì.

Yorùbá Publications (1987-2025)
Jáde
Wọlé
  • Yorùbá
  • Fi Ráńṣẹ́
  • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
  • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
  • Àdéhùn Nípa Lílò
  • Òfin
  • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
  • JW.ORG
  • Wọlé
Fi Ráńṣẹ́