-
Diutarónómì 28:63Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
-
-
63 “Bí inú Jèhófà ṣe dùn nígbà kan láti mú kí nǹkan máa lọ dáadáa fún yín, kí ẹ sì pọ̀ rẹpẹtẹ, bẹ́ẹ̀ náà ni inú Jèhófà ṣe máa dùn láti pa yín run kó sì pa yín rẹ́; ẹ sì máa pa run kúrò ní ilẹ̀ tí ẹ fẹ́ lọ gbà.
-
-
1 Àwọn Ọba 14:16Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
-
-
16 Yóò pa Ísírẹ́lì tì nítorí àwọn ẹ̀ṣẹ̀ tí Jèróbóámù dá àti èyí tó mú kí Ísírẹ́lì dá.”+
-
-
Míkà 1:6Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
-
-
6 Màá sọ Samáríà di àwókù ilé inú oko,
Yóò di ibi tí wọ́n ń gbin àjàrà sí;
Màá ju* àwọn òkúta rẹ̀ sínú àfonífojì,
Èmi yóò sì hú àwọn ìpìlẹ̀ rẹ̀ síta.
-