ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • Diutarónómì 28:45
    Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
    • 45 “Ó dájú pé gbogbo ègún+ yìí máa wá sórí rẹ, ó máa tẹ̀ lé ọ, ó sì máa bá ọ, títí o fi máa pa run,+ torí pé o ò tẹ̀ lé àṣẹ àti òfin Jèhófà Ọlọ́run rẹ tó pa láṣẹ+ fún ọ, láti fi hàn pé ò ń fetí sí ohùn rẹ̀.

  • Diutarónómì 28:63
    Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
    • 63 “Bí inú Jèhófà ṣe dùn nígbà kan láti mú kí nǹkan máa lọ dáadáa fún yín, kí ẹ sì pọ̀ rẹpẹtẹ, bẹ́ẹ̀ náà ni inú Jèhófà ṣe máa dùn láti pa yín run kó sì pa yín rẹ́; ẹ sì máa pa run kúrò ní ilẹ̀ tí ẹ fẹ́ lọ gbà.

  • 1 Àwọn Ọba 14:16
    Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
    • 16 Yóò pa Ísírẹ́lì tì nítorí àwọn ẹ̀ṣẹ̀ tí Jèróbóámù dá àti èyí tó mú kí Ísírẹ́lì dá.”+

  • Hósíà 1:4
    Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
    • 4 Lẹ́yìn náà, Jèhófà sọ fún un pé: “Pe orúkọ rẹ̀ ní Jésírẹ́lì,* torí pé ní ìgbà díẹ̀ sí i, màá pe ilé Jéhù+ wá jíhìn fún ìtàjẹ̀sílẹ̀ tó wáyé ní Jésírẹ́lì, màá sì fòpin sí ìṣàkóso ilé Ísírẹ́lì.+

  • Émọ́sì 5:27
    Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
    • 27 Màá sì rán yín lọ sí ìgbèkùn ní ìkọjá Damásíkù,’+ ni ẹni tí orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Jèhófà Ọlọ́run àwọn ọmọ ogun wí.”+

  • Míkà 1:6
    Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
    •  6 Màá sọ Samáríà di àwókù ilé inú oko,

      Yóò di ibi tí wọ́n ń gbin àjàrà sí;

      Màá ju* àwọn òkúta rẹ̀ sínú àfonífojì,

      Èmi yóò sì hú àwọn ìpìlẹ̀ rẹ̀ síta.

Yorùbá Publications (1987-2025)
Jáde
Wọlé
  • Yorùbá
  • Fi Ráńṣẹ́
  • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
  • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
  • Àdéhùn Nípa Lílò
  • Òfin
  • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
  • JW.ORG
  • Wọlé
Fi Ráńṣẹ́