33 Kí o fi aṣọ ìdábùú náà kọ́ sábẹ́ àwọn ìkọ́, kí o sì gbé àpótí Ẹ̀rí náà+ wọnú ibi tí aṣọ ìdábùú náà bò. Aṣọ ìdábùú náà ni kí ẹ fi pín Ibi Mímọ́+ àti Ibi Mímọ́ Jù Lọ.+
6 Nígbà náà, àwọn àlùfáà gbé àpótí májẹ̀mú Jèhófà wá sí àyè rẹ̀,+ ní yàrá inú lọ́hùn-ún ilé náà, ìyẹn Ibi Mímọ́ Jù Lọ, wọ́n gbé e sí abẹ́ ìyẹ́ apá àwọn kérúbù.+
24 Torí Kristi ò wọnú ibi mímọ́ tí wọ́n fi ọwọ́ ṣe,+ tó jẹ́ àpẹẹrẹ ohun gidi,+ àmọ́ ọ̀run gangan ló wọ̀ lọ,+ tó fi jẹ́ pé ó ń fara hàn báyìí níwájú* Ọlọ́run nítorí wa.+