Ẹ́kísódù 34:26 Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun 26 “Kí o mú èyí tó dáa jù nínú àwọn èso tó kọ́kọ́ pọ́n ní ilẹ̀ rẹ wá sí ilé Jèhófà Ọlọ́run rẹ.+ “O ò gbọ́dọ̀ se ọmọ ewúrẹ́ nínú wàrà ìyá rẹ̀.”+ Nọ́ńbà 15:18, 19 Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun 18 “Sọ fún àwọn ọmọ Ísírẹ́lì pé, ‘Tí ẹ bá dé ilẹ̀ tí mò ń mú yín lọ, 19 tí ẹ sì jẹ èyíkéyìí nínú oúnjẹ* ilẹ̀ náà,+ kí ẹ mú ọrẹ wá fún Jèhófà. Diutarónómì 26:2 Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun 2 kí o mú lára gbogbo ohun* tó bá kọ́kọ́ so ní ilẹ̀ náà, èyí tí o bá kó jọ ní ilẹ̀ rẹ tí Jèhófà Ọlọ́run rẹ fẹ́ fún ọ, kí o kó o sínú apẹ̀rẹ̀, kí o sì lọ sí ibi tí Jèhófà Ọlọ́run rẹ bá yàn pé kí orúkọ rẹ̀ máa wà.+
26 “Kí o mú èyí tó dáa jù nínú àwọn èso tó kọ́kọ́ pọ́n ní ilẹ̀ rẹ wá sí ilé Jèhófà Ọlọ́run rẹ.+ “O ò gbọ́dọ̀ se ọmọ ewúrẹ́ nínú wàrà ìyá rẹ̀.”+
18 “Sọ fún àwọn ọmọ Ísírẹ́lì pé, ‘Tí ẹ bá dé ilẹ̀ tí mò ń mú yín lọ, 19 tí ẹ sì jẹ èyíkéyìí nínú oúnjẹ* ilẹ̀ náà,+ kí ẹ mú ọrẹ wá fún Jèhófà.
2 kí o mú lára gbogbo ohun* tó bá kọ́kọ́ so ní ilẹ̀ náà, èyí tí o bá kó jọ ní ilẹ̀ rẹ tí Jèhófà Ọlọ́run rẹ fẹ́ fún ọ, kí o kó o sínú apẹ̀rẹ̀, kí o sì lọ sí ibi tí Jèhófà Ọlọ́run rẹ bá yàn pé kí orúkọ rẹ̀ máa wà.+