ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • 2 Sámúẹ́lì 19:25-27
    Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
    • 25 Nígbà tó dé sí* Jerúsálẹ́mù láti pàdé ọba, ọba bi í pé: “Kí ló dé tí o ò fi bá mi lọ, Méfíbóṣétì?” 26 Ó fèsì pé: “Olúwa mi ọba, ìránṣẹ́ mi+ ló tàn mí. Nítorí ìránṣẹ́ rẹ sọ pé, ‘Jẹ́ kí n di ohun tí wọ́n fi ń jókòó mọ́ kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ mi,* kí n lè gùn ún, kí n sì bá ọba lọ,’ nítorí arọ+ ni ìránṣẹ́ rẹ. 27 Àmọ́, ó sọ̀rọ̀ èmi ìránṣẹ́ rẹ láìdáa fún ọba.+ Ṣùgbọ́n olúwa mi ọba dà bí áńgẹ́lì Ọlọ́run tòótọ́, torí náà, ohun tó bá dára lójú rẹ ni kí o ṣe.

  • Òwe 25:8
    Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
    •  8 Má fi ìkánjú gbé ọ̀rọ̀ lọ sílé ẹjọ́,

      Àbí kí lo máa ṣe tí ọmọnìkejì rẹ bá kàn ọ́ lábùkù?+

Yorùbá Publications (1987-2025)
Jáde
Wọlé
  • Yorùbá
  • Fi Ráńṣẹ́
  • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
  • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
  • Àdéhùn Nípa Lílò
  • Òfin
  • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
  • JW.ORG
  • Wọlé
Fi Ráńṣẹ́