ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • 2 Àwọn Ọba 5:20-22
    Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
    • 20 Géhásì,+ ìránṣẹ́ Èlíṣà èèyàn Ọlọ́run tòótọ́+ sọ lọ́kàn ara rẹ̀ pé: ‘Ṣé bí ọ̀gá mi á ṣe jẹ́ kí Náámánì ará Síríà+ yìí lọ láìgba ohun tó mú wá nìyẹn? Bí Jèhófà ti wà láàyè, màá sá tẹ̀ lé e, màá sì gba nǹkan kan lọ́wọ́ rẹ̀.’ 21 Torí náà, Géhásì sá tẹ̀ lé Náámánì. Nígbà tí Náámánì rí i pé ẹnì kan ń sáré tẹ̀ lé òun, ó sọ̀ kalẹ̀ lórí kẹ̀kẹ́ ẹṣin rẹ̀ láti pàdé rẹ̀, ó sì sọ pé: “Ṣé àlàáfíà ni?” 22 Ó fèsì pé: “Àlàáfíà ni. Ọ̀gá mi ló rán mi, ó ní, ‘Wò ó! Àwọn ọ̀dọ́kùnrin méjì lára àwọn ọmọ wòlíì ṣẹ̀ṣẹ̀ dé sọ́dọ̀ mi láti agbègbè olókè Éfúrémù. Jọ̀ọ́, fún wọn ní tálẹ́ńtì fàdákà kan àti ìpààrọ̀ aṣọ méjì.’”+

  • Jeremáyà 17:11
    Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
    • 11 Bí ẹyẹ àparò tó máa ń sàba lórí ẹyin tí kì í ṣe tirẹ̀,

      Bẹ́ẹ̀ ni ẹni tó ń fi èrú* kó ọrọ̀ jọ.+

      Wọ́n á fi í sílẹ̀ ní ọ̀sán gangan ayé rẹ̀,

      Ní ìkẹyìn, á wá hàn pé òmùgọ̀ ni.”

  • 1 Tímótì 6:9
    Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
    • 9 Àmọ́ àwọn tó pinnu pé àwọn fẹ́ di ọlọ́rọ̀ máa ń kó sínú ìdẹwò àti ìdẹkùn+ àti ọ̀pọ̀ ìfẹ́ ọkàn tí kò bọ́gbọ́n mu, tó sì lè pani lára, èyí tó ń mú kí àwọn èèyàn pa run kí wọ́n sì ṣègbé.+

Yorùbá Publications (1987-2025)
Jáde
Wọlé
  • Yorùbá
  • Fi Ráńṣẹ́
  • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
  • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
  • Àdéhùn Nípa Lílò
  • Òfin
  • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
  • JW.ORG
  • Wọlé
Fi Ráńṣẹ́