-
2 Kíróníkà 20:5, 6Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
-
-
5 Nígbà náà, Jèhóṣáfátì dìde láàárín ìjọ Júdà àti ti Jerúsálẹ́mù nínú ilé Jèhófà níwájú àgbàlá tuntun, 6 ó sì sọ pé:
“Ìwọ Jèhófà Ọlọ́run àwọn baba ńlá wa, ṣebí ìwọ ni Ọlọ́run ní ọ̀run;+ ṣebí ìwọ lò ń ṣàkóso lórí gbogbo ìjọba àwọn orílẹ̀-èdè?+ Ọwọ́ rẹ ni agbára àti okun wà, kò sì sẹ́ni tó lè dojú kọ ọ́.+
-
-
Àìsáyà 43:13Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
-
-
Tí mo bá ń ṣe nǹkan kan, ta ló lè dá mi dúró?”+
-