Jeremáyà 50:19 Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun 19 Màá mú Ísírẹ́lì pa dà sí ibi ìjẹko rẹ̀,+ á jẹko ní Kámẹ́lì àti ní Báṣánì,+ á* sì ní ìtẹ́lọ́rùn lórí àwọn òkè Éfúrémù+ àti ti Gílíádì.’”+ Ìsíkíẹ́lì 34:14 Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun 14 Èmi yóò bọ́ wọn ní ibi ìjẹko tó dáa, ilẹ̀ tí wọ́n á sì ti máa jẹko yóò wà lórí àwọn òkè gíga Ísírẹ́lì.+ Wọ́n á dùbúlẹ̀ síbẹ̀, níbi ìjẹko tó dáa,+ orí ilẹ̀ tó sì dáa jù lórí àwọn òkè Ísírẹ́lì ni wọ́n á ti máa jẹ ewéko.” Míkà 2:12 Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun 12 Ẹ̀yin ilé Jékọ́bù, èmi yóò kó gbogbo yín jọ;Ó dájú pé màá kó àwọn tó ṣẹ́ kù ní Ísírẹ́lì jọ.+ Màá mú kí wọ́n wà ní ìṣọ̀kan, bí àgùntàn ní ilé ẹran,Bí agbo ẹran ní pápá ìjẹko wọn;+Ariwo àwọn èèyàn máa gba ibẹ̀ kan.’+
19 Màá mú Ísírẹ́lì pa dà sí ibi ìjẹko rẹ̀,+ á jẹko ní Kámẹ́lì àti ní Báṣánì,+ á* sì ní ìtẹ́lọ́rùn lórí àwọn òkè Éfúrémù+ àti ti Gílíádì.’”+
14 Èmi yóò bọ́ wọn ní ibi ìjẹko tó dáa, ilẹ̀ tí wọ́n á sì ti máa jẹko yóò wà lórí àwọn òkè gíga Ísírẹ́lì.+ Wọ́n á dùbúlẹ̀ síbẹ̀, níbi ìjẹko tó dáa,+ orí ilẹ̀ tó sì dáa jù lórí àwọn òkè Ísírẹ́lì ni wọ́n á ti máa jẹ ewéko.”
12 Ẹ̀yin ilé Jékọ́bù, èmi yóò kó gbogbo yín jọ;Ó dájú pé màá kó àwọn tó ṣẹ́ kù ní Ísírẹ́lì jọ.+ Màá mú kí wọ́n wà ní ìṣọ̀kan, bí àgùntàn ní ilé ẹran,Bí agbo ẹran ní pápá ìjẹko wọn;+Ariwo àwọn èèyàn máa gba ibẹ̀ kan.’+