ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • Diutarónómì 4:30
    Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
    • 30 Tí wàhálà tó le gan-an bá dé bá ọ, tí gbogbo nǹkan yìí sì wá ṣẹlẹ̀ sí ọ, wàá pa dà sọ́dọ̀ Jèhófà Ọlọ́run rẹ, wàá sì fetí sí ohùn rẹ̀.+

  • Sáàmù 80:3
    Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
    •  3 Ọlọ́run, mú wa bọ̀ sípò;+

      Jẹ́ kí ojú rẹ tàn sí wa lára, kí a lè rí ìgbàlà.+

  • Sáàmù 85:4
    Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
    •  4 Mú wa bọ̀ sípò,* Ọlọ́run ìgbàlà wa,

      Kí o má sì bínú sí wa mọ́.+

  • Jeremáyà 31:18
    Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
    • 18 “Mo ti gbọ́ tí Éfúrémù ń kérora,

      ‘O ti tọ́ mi sọ́nà, mo sì ti gba ìtọ́sọ́nà,

      Bí ọmọ màlúù tí a kò fi iṣẹ́ kọ́.

      Mú mi pa dà, màá sì ṣe tán láti yí pa dà,

      Nítorí ìwọ ni Jèhófà Ọlọ́run mi.

Yorùbá Publications (1987-2025)
Jáde
Wọlé
  • Yorùbá
  • Fi Ráńṣẹ́
  • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
  • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
  • Àdéhùn Nípa Lílò
  • Òfin
  • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
  • JW.ORG
  • Wọlé
Fi Ráńṣẹ́