ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • Sáàmù 137:8, 9
    Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
    • 8 Ìwọ ọmọbìnrin Bábílónì, tí kò ní pẹ́ di ahoro,+

      Aláyọ̀ ni ẹni tó máa san ọ́ lẹ́san

      Lórí ohun tí o ṣe sí wa.+

      9 Aláyọ̀ ni ẹni tó máa gba àwọn ọmọ rẹ lọ́wọ́ rẹ,

      Tí á sì là wọ́n mọ́ àpáta.+

  • Àìsáyà 51:22, 23
    Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
    • 22 Ohun tí Olúwa rẹ, Jèhófà sọ nìyí, Ọlọ́run rẹ, tó ń gbèjà àwọn èèyàn rẹ̀:

      “Wò ó! Màá gba ife tó ń múni ta gọ̀ọ́gọ̀ọ́ kúrò lọ́wọ́ rẹ,+

      Aago náà, ife ìbínú mi;

      O ò ní mu ún mọ́ láé.+

      23 Màá fi sí ọwọ́ àwọn tó ń dá ọ lóró,+

      Àwọn tó sọ fún ọ* pé, ‘Tẹ̀ ba ká lè rìn lórí rẹ!’

      O wá sọ ẹ̀yìn rẹ di ilẹ̀,

      Bí ojú ọ̀nà tí wọ́n máa rìn kọjá.”

Yorùbá Publications (1987-2025)
Jáde
Wọlé
  • Yorùbá
  • Fi Ráńṣẹ́
  • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
  • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
  • Àdéhùn Nípa Lílò
  • Òfin
  • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
  • JW.ORG
  • Wọlé
Fi Ráńṣẹ́