ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • Jeremáyà 31:33
    Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
    • 33 “Nítorí májẹ̀mú tí màá bá ilé Ísírẹ́lì dá lẹ́yìn ìgbà yẹn nìyí,” ni Jèhófà wí. “Màá fi òfin mi sínú wọn,+ inú ọkàn wọn sì ni màá kọ ọ́ sí.+ Màá di Ọlọ́run wọn, wọ́n á sì di èèyàn mi.”+

  • Ìsíkíẹ́lì 36:28
    Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
    • 28 Ẹ ó wá máa gbé ní ilẹ̀ tí mo fún àwọn baba ńlá yín, ẹ ó di èèyàn mi, màá sì di Ọlọ́run yín.’+

  • Sekaráyà 13:9
    Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
    •  9 Èmi yóò fi ìdá kẹta sínú iná;

      Èmi yóò yọ́ wọn mọ́ bí wọ́n ṣe ń yọ́ fàdákà mọ́,

      Èmi yóò sì yẹ̀ wọ́n wò bí wọ́n ṣe ń yẹ wúrà wò.+

      Wọ́n á ké pe orúkọ mi,

      Èmi yóò sì dá wọn lóhùn.

      Màá sọ pé, ‘Èèyàn mi ni wọ́n,’+

      Wọ́n á sì sọ pé, ‘Jèhófà ni Ọlọ́run wa.’”

Yorùbá Publications (1987-2025)
Jáde
Wọlé
  • Yorùbá
  • Fi Ráńṣẹ́
  • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
  • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
  • Àdéhùn Nípa Lílò
  • Òfin
  • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
  • JW.ORG
  • Wọlé
Fi Ráńṣẹ́