ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • Mátíù 27:15-18
    Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
    • 15 Tí wọ́n bá ń ṣe àjọyọ̀, ó jẹ́ àṣà gómìnà láti tú ẹlẹ́wọ̀n kan sílẹ̀ fún àwọn èèyàn, ẹnikẹ́ni tí wọ́n bá fẹ́.+ 16 Àkókò yẹn gan-an ni ẹlẹ́wọ̀n burúkú kan tó lókìkí wà ní àhámọ́ wọn, Bárábà lorúkọ rẹ̀. 17 Torí náà, nígbà tí wọ́n kóra jọ, Pílátù sọ fún wọn pé: “Ta lẹ fẹ́ kí n tú sílẹ̀ fún yín, ṣé Bárábà ni àbí Jésù tí wọ́n ń pè ní Kristi?” 18 Torí Pílátù mọ̀ pé wọ́n ń ṣe ìlara rẹ̀ ni wọ́n ṣe fà á lé òun lọ́wọ́.

  • Jòhánù 18:39
    Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
    • 39 Àmọ́, ẹ ní àṣà kan, pé kí n máa tú ẹnì kan sílẹ̀ fún yín nígbà Ìrékọjá.+ Torí náà, ṣé ẹ fẹ́ kí n tú Ọba Àwọn Júù sílẹ̀ fún yín?”

Yorùbá Publications (1987-2025)
Jáde
Wọlé
  • Yorùbá
  • Fi Ráńṣẹ́
  • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
  • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
  • Àdéhùn Nípa Lílò
  • Òfin
  • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
  • JW.ORG
  • Wọlé
Fi Ráńṣẹ́