ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • scl ojú ìwé 107-108
  • Ogun

Kò sí fídíò kankan ní apá yìí.

Má bínú, fídíò yìí kò jáde.

  • Ogun
  • Àwọn Ẹsẹ Bíbélì Tó Lè Ran Àwa Kristẹni Lọ́wọ́
Àwọn Ẹsẹ Bíbélì Tó Lè Ran Àwa Kristẹni Lọ́wọ́
scl ojú ìwé 107-108

Ogun

Kí nìdí tí kò fi yẹ kó yà wá lẹ́nu pé ogun ń jà lọ́pọ̀ ibi lásìkò tá a wà yìí?

Mt 24:3, 4, 7, 8

  • Àpẹẹrẹ inú Bíbélì:

    • Da 11:40—Jèhófà mú kí wòlíì Dáníẹ́lì rí ìran kan nípa àwọn ọjọ́ ìkẹyìn tá a wà yìí, nínú ìran náà, ó rí i pé àwọn orílẹ̀-èdè alágbára méjì ń bára wọn díje, wọ́n sì ń figa gbága

    • Ifi 6:1-4—Àpọ́sítélì Jòhánù rí ẹṣin aláwọ̀ iná kan tó ń ṣàpẹẹrẹ ogun, ẹni tó jókòó sórí ẹṣin náà sì ní àṣẹ “láti mú àlàáfíà kúrò ní ayé”

Kí ni Jèhófà máa ṣe sí ogun?

Sm 46:8, 9; Ais 9:6, 7; Mik 4:3

Kí nìdí táwa Kristẹni kì í fi í dá sí ogun?

Ais 2:2, 4

Tún wo “Ìjọba—Àwa Kristẹni Kì Í Dá Sí Ogun àti Ọ̀rọ̀ Òṣèlú”

Kí nìdí tí Jèhófà àti Jésù fi máa jagun, àwọn wo ni wọ́n sì máa bá jagun?

Sm 45:3-5; Jer 25:31-33; Ifi 19:11

Irú ogun wo làwọn Kristẹni tòótọ́ máa ń jà?

Ro 13:12; 2Kọ 10:3, 4; Ef 6:11-17

Báwo làwa Kristẹni ṣe lè yẹra fún àwọn ìwà tó lè yọrí sí ogun, irú bíi kéèyàn jẹ́ oníjà tàbí kó máa gbẹ̀san?

Ro 12:17-21; Ga 5:14, 15; Tit 3:1, 2; Jem 4:1-3

    Yorùbá Publications (1987-2025)
    Jáde
    Wọlé
    • Yorùbá
    • Fi Ráńṣẹ́
    • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
    • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
    • Àdéhùn Nípa Lílò
    • Òfin
    • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
    • JW.ORG
    • Wọlé
    Fi Ráńṣẹ́