ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • w02 12/15 ojú ìwé 31
  • Atọ́ka Àwọn Àkòrí Inú Ilé Ìṣọ́ 2002

Kò sí fídíò kankan ní apá yìí.

Má bínú, fídíò yìí kò jáde.

  • Atọ́ka Àwọn Àkòrí Inú Ilé Ìṣọ́ 2002
  • Ilé Ìṣọ́ Tí Ń Kéde Ìjọba Jehofa—2002
  • Ìsọ̀rí
  • ÀWỌN ẸLẸ́RÌÍ JÈHÓFÀ
  • ÀWỌN OLÙPÒKÌKÍ ÌJỌBA RÒYÌN
  • BÍBÉLÌ
  • ÌBÉÈRÈ LÁTI ỌWỌ́ ÀWỌN ÒǸKÀWÉ
  • ÌGBÉSÍ AYÉ ÀTI ÀNÍMỌ́ KRISTẸNI
  • ÌTÀN ÌGBÉSÍ AYÉ
  • JÈHÓFÀ
  • JÉSÙ KRISTI
  • LÁJORÍ ÀPILẸ̀KỌ FÚN ÌKẸ́KỌ̀Ọ́
  • Ọ̀KAN-Ò-JỌ̀KAN
Ilé Ìṣọ́ Tí Ń Kéde Ìjọba Jehofa—2002
w02 12/15 ojú ìwé 31

Atọ́ka Àwọn Àkòrí Inú Ilé Ìṣọ́ 2002

Ó ń tọ́ka sí ìtẹ̀jáde tí àpilẹ̀kọ kọ̀ọ̀kan ti jáde

ÀWỌN ẸLẸ́RÌÍ JÈHÓFÀ

Akitiyan Tó Ń Gbé Ìlànà Ìwà Rere Ga (Mòsáńbíìkì), 11/15

Àpéjọ Àgbáyé Yóò Wáyé Lọ́dún 2003, 7/1

Àpéjọ “Àwọn Olùkọ́ni ní Ọ̀rọ̀ Ọlọ́run,” 1/15

A Ṣí Àwọn Gbọ̀ngàn Ìjọba Sílẹ̀ fún Gbogbo Èèyàn Láti Wò, 11/1

Àwọn Ajẹ́rìíkú Òde Òní (Sweden), 2/1

Àwọn Alátìlẹyìn Ìjọsìn Tòótọ́ (ọrẹ), 11/1

Àwọn Èwe Tó Ń Tuni Lára, 9/15

Àwọn Ìpàdé, 3/15

Àwọn Òkè Ńlá Philippines, 4/15

Àwọn Orílẹ̀-Èdè Balkan (Ìtumọ̀ Ayé Tuntun), 10/15

Àwọn Ọ̀dọ́ Tó Fẹ́ràn Òtítọ́, 10/1

Àwọn Pásítọ̀ Tó Mọyì Àwọn Ìwé Tí Russell Kọ, 4/15

Ayẹyẹ Ìkẹ́kọ̀ọ́yege ní Gílíádì, 6/15, 12/15

Bí Ọmọ Kan Ṣe Ran Bàbá Rẹ̀ Lọ́wọ́, 5/1

Gbọ̀ngàn Ìjọba Kan Gba Àmì Ẹ̀yẹ (Finland), 10/1

Ìbísí Bíbùáyà Mú Kí Ìmúgbòòrò Pọn Dandan (Àwọn Gbọ̀ngàn Ìjọba), 5/15

“Ìdí Tí Mo Fi Dá Owó Yín Padà,” 8/15

‘Ìfẹ́ Wa Ti Jinlẹ̀ Sí I’ (òkè ayọnáyèéfín ní Japan), 3/1

Ìpàdé Ọdọọdún ti 2001, 4/1

Iṣẹ́ Àtàtà Ń Yin Ọlọ́run Lógo (Ítálì), 1/15

Kí Ló Gbà Láti Ní Ẹ̀rí Ọkàn Mímọ́? 2/15

Lórí Tábìlì Ọ̀gákọ̀ (R. G. Smith), 12/1

“Máa Ṣe Ohun Rere sí Gbogbo Ènìyàn,” 7/15

Ọmọdé Gbọ́n, Àgbà Gbọ́n (àwọn ọmọdé tó ń dáwó), 2/1

Wọ́n Ti Mọ̀wé Kà (Solomon Islands), 8/15

ÀWỌN OLÙPÒKÌKÍ ÌJỌBA RÒYÌN

2/1, 4/1, 6/1, 8/1, 10/1, 11/1

BÍBÉLÌ

Akitiyan Láti Tẹ Bíbélì Lédè Gíríìkì Òde Òní, 11/15

Ìtumọ̀ Septuagint, 9/15

Ọba Henry Kẹjọ àti Bíbélì, 1/1

ÌBÉÈRÈ LÁTI ỌWỌ́ ÀWỌN ÒǸKÀWÉ

Àánú Jèhófà ń pẹ̀rọ̀ sí ìdájọ́ òdodo rẹ̀ kẹ̀? 3/1

Àgbàlá níbi tí “ogunlọ́gọ̀ ńlá” ti ń sìn (Ìṣí 7:15), 5/1

Àwọn ìgbà wo ló yẹ kí Kristẹni obìnrin borí rẹ̀? 7/15

Gbígbàdúrà láìsọ pé “ní orúkọ Jésù,” 4/15

Ìgbéyàwó láàárín àwọn ìbátan, 2/1

Ìtumọ̀ “dúró títí dé orí ẹ̀jẹ̀” (Héb 12:4), 2/15

Iye àwọn ọmọ Jésè (1 Sa 16:10, 11; 1 Kr 2:13-15), 9/15

Lúsíférì (Isa 14:12, KJ), 9/15

Ǹjẹ́ àìpé Màríà ran Jésù? 3/15

Ǹjẹ́ Ébẹ́lì mọ̀ pé ó pọ̀n dandan láti fi ẹran rúbọ? 8/1

Ǹjẹ́ ó bójú mu láti lọ sọ ọ̀rọ̀ ìsìnkú ẹni tó pa ara rẹ̀? 6/15

Ǹjẹ́ ó bọ́gbọ́n mu láti lọ bá wọn ṣètò ìsìnkú tàbí ìgbéyàwó nínú ṣọ́ọ̀ṣì? 5/15

Ǹjẹ́ ó lòdì láti kọ́ iyàn tí owó rẹ̀ kò jù táṣẹ́rẹ́? 11/1

Ọmọ títọ́ nínú ilé tí ìsìn ti yàtọ̀ síra, 8/15

Ṣé dandan ni ká ri aláàbọ̀ ara tàbí ẹni tí ipò rẹ̀ gbẹgẹ́ gan-an bọmi pátápátá? 6/1

Ṣé gbogbo ìgbà la gbọ́dọ̀ san ẹ̀jẹ́ tá a bá jẹ́ fún Ọlọ́run? 11/15

Ṣe ọ̀pọ̀ rẹpẹtẹ la máa tàn jẹ nígbà ìdánwò ìkẹyìn? (Ìṣí 20:8), 12/1

Ríra ilẹ̀ Gbọ̀ngàn Ìjọba lọ́wọ́ àwọn ẹlẹ́sìn mìíràn kẹ̀? 10/15

ÌGBÉSÍ AYÉ ÀTI ÀNÍMỌ́ KRISTẸNI

Agbára Láti Ronú, 8/15

‘Ẹ Máa Dárí Ji Ara Yín Fàlàlà,’ 9/1

“Ẹ Máa Ṣe Olùṣọ́ Àgùntàn Agbo Ọlọ́run,” 11/15

Ẹ̀mí Ìfọ̀rọ̀rora-Ẹni-Wò, 4/15

Ẹ̀yin Alàgbà—Ẹ Kọ́ Àwọn Ẹlòmíràn, 1/1

Fífi Ìfẹ́ Hàn Nínú Agbo Ìdílé, 12/15

Fún Ọwọ́ Rẹ Lókun, 12/1

Gbin Òdodo, Kí O sì Ká Inú-Rere-Onífẹ̀ẹ́ (Òwe 11), 7/15

Gbogbo Orílẹ̀-Èdè Ni Ọlọ́run Tẹ́wọ́ Gbà, 4/1

Ibi Ìfarapamọ́sí Kúrò Lọ́wọ́ Ẹ̀fúùfù, 2/15

“Ìgbàlà Jẹ́ Ti Jèhófà” (ètò ìfọkànsin orílẹ̀-èdè ẹni), 9/15

Ìgbà Wo Ni Jèhófà Máa Ń Bù Kún Ìsapá Tí A Fi Taratara Ṣe? 8/1

Ìmọ́tótó, 2/1

Ìnìkanwà, 3/15

Irú Ojú Wo Ló Yẹ Ká Máa Fi Wo Àdánwò? 9/1

Ìwà Títọ́, 8/15

Ìwà Títọ́ Ń Ṣamọ̀nà Àwọn Adúróṣánṣán, (Òwe 11) 5/15

Lílo Ìgbésí Ayé Wa Lọ́nà Tí Inú Jèhófà Dùn Sí, 11/15

“Máa Kọ́ Ara Rẹ,” 10/1

Ǹjẹ́ Bó O Ṣe Ń Kọ́ni Múná Dóko? 7/1

Oríyìn, 11/1

Owú Jíjẹ, 10/15

Ọ̀rọ̀ Àṣírí, 6/15

Pípàdé Pọ̀, 11/15

Rírìn ní Ipa Ọ̀nà Jèhófà, 7/1

Títọ́ Ọmọ Nílẹ̀ Òkèèrè, 10/15

Títọrọ Àforíjì, 11/1

‘Wíwàásù Ọ̀rọ̀ Náà’ Ń Mú Ìtura Wá, 1/15

ÌTÀN ÌGBÉSÍ AYÉ

Àǹfààní Kíkópa Nínú Ìmúgbòòrò Iṣẹ́ Náà Lẹ́yìn Ogun (F. Hoffmann), 10/1

A Ò Kúrò Nídìí Iṣẹ́ Tá A Yàn fún Wa (H. Bruder), 11/1

Ẹgbẹ́ Àwọn Ará Kárí Ayé fún Mi Lókun (T. Kangale), 7/1

Fífi Ẹ̀mí Ìfara-Ẹni-Rúbọ Sìn (D. Rendell), 3/1

Gbígbin Ìfẹ́ fún Jèhófà Sọ́kàn Àwọn Ọmọ Wa (W. Matzen), 5/1

Ibi Tá A Ti Ń Ṣiṣẹ́ Míṣọ́nnárì Di Ilé Wa (D. Waldron), 12/1

Ìfọkànsin Ọlọ́run Mú Èrè Wá fún Mi (W. Aihinoria), 6/1

Jèhófà Kọ́ Wa Ní Ìfaradà (A. Apostolidis), 2/1

Jèhófà Ti Fún Mi ní “Agbára Tí Ó Ré Kọjá Ìwọ̀n Ti Ẹ̀dá” (H. Marks), 1/1

“Mi Ò Ní Yí Ohunkóhun Padà!” (G. Allen), 9/1

Mo Gbó Mo sì Tọ́ (M. Smith), 8/1

JÈHÓFÀ

Gbẹ́kẹ̀ Lé Jèhófà, Tó Jẹ́ Ẹni Gidi, 1/15

Lẹ́tà Mẹ́rin Tó Dúró fún Orúkọ Ọlọ́run Wà Nínú Ìtumọ̀ Septuagint, 6/1

Ta Ni Ọlọ́run? 5/15

JÉSÙ KRISTI

Ìbí Jésù, 12/15

LÁJORÍ ÀPILẸ̀KỌ FÚN ÌKẸ́KỌ̀Ọ́

A Wẹ̀ Wá Mọ́ Láti Jẹ́ Èèyàn fún Iṣẹ́ Àtàtà, 6/1

Àwọn Ìbùkún Ìhìn Rere, 1/1

Àwọn Kristẹni Ń Jọ́sìn ní Ẹ̀mí àti Òtítọ́, 7/15

Àwọn Kristẹni Tí Kì Í Dá sí Tọ̀túntòsì Láwọn Ọjọ́ Ìkẹyìn, 11/1

“Àwọn Ohun Ọlá Ńlá Ọlọ́run” Ń Ru Wá Sókè, 8/1

Àwọn Wo Ni Yóò La Ọjọ́ Jèhófà Já? 5/1

A Ti Mú Wa Gbára Dì fún Iṣẹ́ Olùkọ́ni Ní Ọ̀rọ̀ Ọlọ́run, 2/15

Báwo Ni Òtítọ́ Ti Ṣeyebíye Tó Lójú Rẹ? 3/1

Dídé Ojú Ìwọ̀n Ohun Tí Ọlọ́run Béèrè Ń Gbé Jèhófà Ga, 5/1

Èé Ṣe Tó Fi Yẹ Kó O Ṣe Batisí? 4/1

“Ènìyàn Mìíràn Kò Tíì Sọ̀rọ̀ Báyìí Rí,” 10/15

Ẹ Fi Ìdúróṣinṣin Tẹrí Ba fún Ọlá Àṣẹ Ọlọ́run, 8/1

Ẹ Fi Ìfọkànsìn Ọlọ́run Kún Ìfaradà Yín, 7/15

“Ẹ Kọ Ojú Ìjà sí Èṣù,” 10/15

Ẹ Máa Fi Ọkàn-Àyà Tó Fẹsẹ̀ Múlẹ̀ Ṣinṣin Sin Jèhófà, 4/1

Ẹ Máa Sìn ní Ìfẹ̀gbẹ́kẹ̀gbẹ́, 11/15

‘Ẹ Pọkàn Pọ̀ Ju Ti Àtẹ̀yìnwá Lọ,’ 9/15

“Ẹ Sún mọ́ Ọlọ́run,” 12/15

“Ẹ Tọ́jú Ìwà Yín Kí Ó Dára Lọ́pọ̀lọpọ̀ Láàárín Àwọn Orílẹ̀-Èdè,” 11/1

Fífarada ‘Ẹ̀gún Nínú Ẹran Ara’ 2/15

Gbádùn Ìdákẹ́kọ̀ọ́ Ọ̀rọ̀ Ọlọ́run, 12/1

Gbogbo Kristẹni Tòótọ́ Ni Ajíhìnrere, 1/1

Ìdákẹ́kọ̀ọ́ Tó Ń Mú Ká Di Olùkọ́ Tó Pegedé, 12/1

Ìmọ́lẹ̀ Ọlọ́run Ń Lé Òkùnkùn Dà Nù! 3/1

Ire Wa Ni Òfin Ọlọ́run Wà Fún, 4/15

Jèhófà Bìkítà fún Yín, 10/15

Jèhófà Fi Ìmọ́lẹ̀ Bu Ẹwà Kún Àwọn Èèyàn Rẹ̀, 7/1

Jèhófà Jẹ́ Aláìlẹ́gbẹ́ Nínú Rere Ṣíṣe, 1/15

Jèhófà Kórìíra Ìwà Àdàkàdekè, 5/1

Jèhófà Ń Bù Kún Àwọn Onígbọràn, Ó sì Ń Dáàbò Bò Wọ́n, 10/1

Jẹ́ Onígbọràn Bí Òpin Ti Ń Sún Mọ́lé, 10/1

Jíjàǹfààní Inú-Rere-Onífẹ̀ẹ́ Jèhófà, 5/15

“Kì Í Bá Wọn Sọ̀rọ̀ Láìsí Àpèjúwe,” 9/1

Kòṣeémáàní Làwa Kristẹni Jẹ́ fún Ara Wa, 11/15

Kristi Ni Aṣáájú Ìjọ Rẹ̀, 3/15

Máa Fara Wé Olùkọ́ Ńlá Náà, 9/1

Máa Fi Àwọn Ìlànà Ọlọ́run Tọ́ Ìṣísẹ̀ Ara Rẹ, 4/15

Máa Fi Inú-Rere-Onífẹ̀ẹ́ Hàn Sáwọn Aláìní, 5/15

Máa Fi Ìwà Rere Kristẹni Kọ́ Ara Rẹ Àtàwọn Ẹlòmíràn, 6/15

Máa Fi Ohun Tó O Ti Kọ́ Sílò, 9/15

Máa Ṣe Bí Ọba, 6/15

Máa Ṣe Rere Nìṣó, 1/15

“Máa Tọ̀ Mí Lẹ́yìn Nígbà Gbogbo,” 8/15

“Mo Fi Àwòṣe Lélẹ̀ fún Yín,” 8/15

Ní Inú Dídùn sí Òdodo Jèhófà, 6/1

Ǹjẹ́ O Ti Rí “Ẹ̀mí Òtítọ́” Náà Gbà? 2/1

Ǹjẹ́ O Wà Lára Àwọn Tí Ọlọ́run Nífẹ̀ẹ́? 2/1

Ògo Jèhófà Tàn Sára Àwọn Èèyàn Rẹ̀, 7/1

Ṣé Lóòótọ́ Lo Gbà Pé Kristi Ni Aṣáájú Wa? 3/15

Wọ́n Fara Da Ẹ̀gún Nínú Ẹran Ara Wọn, 2/15

Wọ́n Ń Bá A Lọ ní Rírìn Nínú Òtítọ́, 7/15

“Yóò sì Sún mọ́ Yín,” 12/15

Ọ̀KAN-Ò-JỌ̀KAN

Aṣáájú Rere, 3/15

Àwọn Aládùúgbò, 9/1

“Àwọn Amòye Mẹ́ta,” 12/15

Àwọn Ère Ìjọsìn, 7/1

Àwọn Èrò Èké Nípa Ikú, 6/1

“Àwọn Ẹni Mímọ́,” 9/15

Àwọn Ìlànà Ọlọ́run Lè Ṣe Ọ́ Láǹfààní, 2/15

Àwọn Ọmọ Ìyá Kan Náà Tí Ìwà Wọ́n Yàtọ̀ Síra (Kéènì àti Ébẹ́lì), 1/15

Àwọn Ọmọlẹ́yìn Waldo, 3/15

Ayé Ìgbàanì Ṣègbé (Ìkún Omi), 3/1

Ẹ̀bi Ta Ni—Ṣé Ẹ̀bi Rẹ Ni àbí Ti Apilẹ̀ Àbùdá Rẹ? 6/1

Ẹ̀kọ́ Àríkọ́gbọ́n Lára Ẹyẹ Àkọ̀, 8/1

Ẹ̀kọ́ Àríkọ́gbọ́n Látinú Ìtàn Róòmù (àwọn eré ìdárayá oníjà àjàkú akátá), 6/15

Gbẹ́kẹ̀ Lé Ọlọ́run Tó Jẹ́ Ẹni Gidi 1/15

Ìbatisí Clovis, 3/1

Ibo Lo Ti Lè Rí Ìfọ̀kànbalẹ̀? 4/15

Igi Tó “Ń Sunkún” àti “Omijé” Rẹ̀ Tó Wúlò Púpọ̀, 1/15

Ìgbàgbọ́ àti Ọgbọ́n Orí, Ǹjẹ́ Wọ́n Bára Tan? 4/1

Ìgbàgbọ́ Nínú Ohun Asán, 8/1

Ikú, 6/1

Ìlú Tó Wà Lórí Òkè, 2/1

Iná Ọ̀run Àpáàdì, 7/15

Ìṣòro Aráyé, 6/15

Ìṣòro Jíjẹ́ Aláàbọ̀ Ara Kò Ní Sí Mọ́, 5/1

Ìtùnú Nínú Ayé Oníwàhálà, 10/1

Jóṣúà, 12/1

Kíkun Òkú Lọ́ṣẹ, 3/15

Má Ṣe Jẹ́ Kí A Tàn Ọ́ Jẹ, 7/1

Nikodémù, 2/1

Ǹjẹ́ A Nílò Àwọn Ibi Ìjọsìn? 11/15

Ǹjẹ́ Ìwà Kẹ́lẹ́gbẹ́mẹgbẹ́ Lè Tán Láé? 1/1

Ǹjẹ́ Ó Yẹ Kó O Jẹ́ Ẹni Tó Tutù Lẹ́dàá? 10/1

“Obìnrin Títayọ Lọ́lá” (Rúùtù), 6/15

Ohun Kan Tó Níye Lórí Ju Àwọn Ìṣúra Íjíbítì Lọ (Mósè), 6/15

Ọ̀nà Wo Ló Yẹ Kí Ìsìn Máa Gbà Rí Owó Tó Ń Ná?

Pẹpẹ Kan fún Ọlọ́run Tí Kò Lórúkọ, 7/15

Sátánì—Ṣé Olubi Tó Wà Lóòótọ́ Ni àbí Ẹni Ìtàn Àròsọ Lásán? 10/15

Ṣáfánì àti Ìdílé Rẹ̀, 12/15

Ṣọ́ọ̀ṣì àti Ìjọba ní Ilẹ̀ Ọba Byzantium, 2/15

Tá Ló Yẹ Kó O Jẹ́ Adúróṣinṣin Sí? 8/15

Tertullian, 5/15

“Wò Ó, Ó Lè Dùn Ẹ́ O,” 3/1

Yoga, 8/1

    Yorùbá Publications (1987-2025)
    Jáde
    Wọlé
    • Yorùbá
    • Fi Ráńṣẹ́
    • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
    • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
    • Àdéhùn Nípa Lílò
    • Òfin
    • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
    • JW.ORG
    • Wọlé
    Fi Ráńṣẹ́