ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • w08 11/15 ojú ìwé 1-2
  • Àwọn Ohun Tó Wà Nínú Ìwé Yìí

Kò sí fídíò kankan ní apá yìí.

Má bínú, fídíò yìí kò jáde.

  • Àwọn Ohun Tó Wà Nínú Ìwé Yìí
  • Ilé Ìṣọ́ Tí Ń Kéde Ìjọba Jehofa—2008
  • Ìsọ̀rí
  • ÀWỌN ÀPILẸ̀KỌ TÁ A MÁA KẸ́KỌ̀Ọ́ NÍ Ọ̀SẸ̀:
  • Ohun Táwọn Àpilẹ̀kọ Tá a Máa Kẹ́kọ̀ọ́ Dá Lé
  • ÀWỌN ÀPILẸ̀KỌ MÍÌ NÍNÚ ÌTẸ̀JÁDE YÌÍ:
Ilé Ìṣọ́ Tí Ń Kéde Ìjọba Jehofa—2008
w08 11/15 ojú ìwé 1-2

Àwọn Ohun Tó Wà Nínú Ìwé Yìí

November 15, 2008

Ẹ̀dà Tó Wà Fún Ìkẹ́kọ̀ọ́

ÀWỌN ÀPILẸ̀KỌ TÁ A MÁA KẸ́KỌ̀Ọ́ NÍ Ọ̀SẸ̀:

January 5-11

Ẹ Ṣèrànwọ́ Fáwọn Tó Ṣáko Lọ Kí Wọ́n Lè Pa Dà Sínú Agbo

OJÚ ÌWÉ 8

ÀWỌN ORIN TÁ A Ó KỌ: 47, 101

January 12-18

Ẹ Ṣèrànwọ́ fún Wọn Kí Wọ́n Lè Tètè Pa Dà Láìjáfara!

OJÚ ÌWÉ 12

ÀWỌN ORIN TÁ A Ó KỌ: 116, 184

January 19-25

Ẹ Máa Tẹ̀ Lé Ìlànà Ìwé Mímọ́ Lórí Ọ̀rọ̀ Ìtọ́jú Ara

OJÚ ÌWÉ 23

ÀWỌN ORIN TÁ A Ó KỌ: 44, 182

January 26–February 1

“Ẹ Kọ Ojú Ìjà sí Èṣù” bí Jésù Ti Ṣe

OJÚ ÌWÉ 27

ÀWỌN ORIN TÁ A Ó KỌ: 174, 191

Ohun Táwọn Àpilẹ̀kọ Tá a Máa Kẹ́kọ̀ọ́ Dá Lé

Àpilẹ̀kọ fún Ìkẹ́kọ̀ọ́ 1 àti 2 OJÚ ÌWÉ 8 sí 16

Kọ́ nípa bí àwọn alàgbà àtàwọn ará ìjọ ṣe lè ṣèrànwọ́ fáwọn akéde tó ti ṣáko lọ kúrò nínú agbo Ọlọ́run. Àpilẹ̀kọ méjèèjì yìí ṣàlàyé ọ̀nà tó o lè gbà ṣèrànwọ́ fáwọn akéde tó di aláìṣiṣẹ́mọ́. Sì tún kíyè sí báwọn ará ìjọ ṣe máa ń tẹ́wọ́ gba àwọn tó bá pa dà sínú ètò Ọlọ́run.

Àpilẹ̀kọ fún Ìkẹ́kọ̀ọ́ 3 OJÚ ÌWÉ 23 sí 27

Kò burú tá a bá ń ṣàníyàn níwọ̀nba nípa ìlera wa. Nítorí náà, àwa Ẹlẹ́rìí Jèhófà máa ń gba ìtọ́jú nílé ìwòsàn, oríṣi àwọn ìtọ́jú mìíràn sì wà tá ò lòdì sí. Àmọ́ ṣá o, ó ṣe pàtàkì pé kéèyàn ní ‘èrò inú tó yè kooro.’ (Títù 2:12) Ju gbogbo ẹ̀ lọ, ó yẹ ká máa bójú tó ìlera wa nípa tẹ̀mí kí àjọṣe tó wà láàárín àwa àti Ọlọ́run lè túbọ̀ dára sí i.

Àpilẹ̀kọ fún Ìkẹ́kọ̀ọ́ 4 OJÚ ÌWÉ 27 sí 31

Kọ́ nípa bí Jésù ṣe fi àpẹẹrẹ lélẹ̀ lórí ọ̀rọ̀ kíkọjú ìjà sí Èṣù. Àpilẹ̀kọ yìí jẹ́ ká rí ìdí tí Ọlọ́run fi fọkàn tán Ọmọ rẹ̀. Ó jẹ́ ká rí bí Jésù ṣe kọjú ìjà sí Èṣù tó sì borí ó sì tún jẹ́ ká rí bí àwa náà ṣe lè ṣe bẹ́ẹ̀.

ÀWỌN ÀPILẸ̀KỌ MÍÌ NÍNÚ ÌTẸ̀JÁDE YÌÍ:

Irú Èèyàn Wo Lo Fẹ́ Jẹ́?

OJÚ ÌWÉ 3

Gbogbo Wọn Ń Fi “Ọkàn Kan” Sin Ọlọ́run

OJÚ ÌWÉ 6

“Máa Lépa Àwọn Ohun Tí Ń Yọrí sí Àlàáfíà”

OJÚ ÌWÉ 17

Ọ̀rọ̀ Jèhófà Yè—Àwọn Kókó Pàtàkì Látinú Ìwé Jákọ́bù, Ìwé Pétérù Kìíní àti Pétérù Kejì

OJÚ ÌWÉ 20

“Ìwé Orin Òkun”—Ìwé Tí Wọ́n Kọ Láàárín Àkókò Méjì Kan

OJÚ ÌWÉ 32

    Yorùbá Publications (1987-2025)
    Jáde
    Wọlé
    • Yorùbá
    • Fi Ráńṣẹ́
    • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
    • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
    • Àdéhùn Nípa Lílò
    • Òfin
    • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
    • JW.ORG
    • Wọlé
    Fi Ráńṣẹ́