ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • scl ojú ìwé 35-36
  • Èso Tẹ̀mí

Kò sí fídíò kankan ní apá yìí.

Má bínú, fídíò yìí kò jáde.

  • Èso Tẹ̀mí
  • Àwọn Ẹsẹ Bíbélì Tó Lè Ran Àwa Kristẹni Lọ́wọ́
Àwọn Ẹsẹ Bíbélì Tó Lè Ran Àwa Kristẹni Lọ́wọ́
scl ojú ìwé 35-36

Èso Tẹ̀mí

Àwọn ìwà wo ni ẹ̀mí mímọ́ lè ràn wá lọ́wọ́ láti ní, kí sì nìdí tó fi yẹ ká lẹ́mìí ìrẹ̀lẹ̀ kí Ọlọ́run tó lè fún wa ní ẹ̀mí mímọ́ rẹ̀?

Ga 5:22, 23; Jem 4:6

  • Àpẹẹrẹ inú Bíbélì:

    • Sm 143:1, 4-11—Nígbà tí Ọba Dáfídì ní ìṣòro tó le gan-an, ó ronú lórí àwọn iṣẹ́ Jèhófà, ó sì bẹ Jèhófà pé kó fún òun ní ẹ̀mí mímọ́

    • Lk 11:9-13—Jésù sọ àpèjúwe kan kó lè rán wa létí pé ó wu Jèhófà láti fún wa ní ẹ̀mí mímọ́ tá a bá béèrè fún un

    Yorùbá Publications (1987-2025)
    Jáde
    Wọlé
    • Yorùbá
    • Fi Ráńṣẹ́
    • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
    • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
    • Àdéhùn Nípa Lílò
    • Òfin
    • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
    • JW.ORG
    • Wọlé
    Fi Ráńṣẹ́