ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • Léfítíkù 20:17
    Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
    • 17 “‘Tí ọkùnrin kan bá bá arábìnrin rẹ̀ tó jẹ́ ọmọ bàbá rẹ̀ tàbí ọmọ ìyá rẹ̀ lò pọ̀, tó rí ìhòòhò obìnrin náà, tí obìnrin náà sì rí ìhòòhò rẹ̀, ohun ìtìjú ni.+ Kí ẹ pa wọ́n níṣojú àwọn ọmọ àwọn èèyàn wọn. Ó ti dójú ti* arábìnrin rẹ̀. Kó jìyà ẹ̀ṣẹ̀ rẹ̀.

  • Diutarónómì 27:22
    Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
    • 22 “‘Ègún ni fún ẹni tó bá bá arábìnrin rẹ̀ sùn, ì báà jẹ́ ọmọ bàbá rẹ̀ tàbí ọmọ ìyá rẹ̀.’+ (Kí gbogbo èèyàn sì sọ pé, ‘Àmín!’)

  • 2 Sámúẹ́lì 13:10-12
    Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
    • 10 Ámínónì wá sọ fún Támárì pé: “Gbé oúnjẹ* náà wá sínú yàrá mi, kí n lè jẹ ẹ́ lọ́wọ́ rẹ.” Torí náà, Támárì gbé kéèkì tó rí bí ọkàn tó ti ṣe wá fún Ámínónì ẹ̀gbọ́n rẹ̀ nínú yàrá. 11 Nígbà tó gbé e wá fún un kó lè jẹ ẹ́, Ámínónì rá a mú, ó sì sọ pé: “Wá sùn tì mí, àbúrò mi.” 12 Àmọ́, ó sọ fún un pé: “Rárá o, ẹ̀gbọ́n mi! Má ṣe kó ẹ̀gàn bá mi, nítorí ẹnikẹ́ni ò gbọ́dọ̀ ṣe irú nǹkan bẹ́ẹ̀ ní Ísírẹ́lì.+ Má ṣe ohun tó ń dójú tini yìí.+

Yorùbá Publications (1987-2025)
Jáde
Wọlé
  • Yorùbá
  • Fi Ráńṣẹ́
  • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
  • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
  • Àdéhùn Nípa Lílò
  • Òfin
  • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
  • JW.ORG
  • Wọlé
Fi Ráńṣẹ́