- 
	                        
            
            2 Kíróníkà 32:21, 22Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
- 
                            - 
                                        21 Lẹ́yìn náà, Jèhófà rán áńgẹ́lì kan, ó sì pa gbogbo jagunjagun tó lákíkanjú + àti àwọn aṣáájú pẹ̀lú àwọn olórí nínú ibùdó ọba Ásíríà, tó fi di pé ìtìjú ló fi pa dà lọ sí ilẹ̀ rẹ̀. Nígbà tó yá, ó wọ ilé* ọlọ́run rẹ̀, ibẹ̀ ni àwọn kan lára àwọn ọmọkùnrin rẹ̀ sì ti fi idà pa á.+ 22 Bí Jèhófà ṣe gba Hẹsikáyà àti àwọn tó ń gbé Jerúsálẹ́mù lọ́wọ́ Senakérúbù ọba Ásíríà nìyẹn àti lọ́wọ́ gbogbo àwọn yòókù, ó sì fún wọn ní ìsinmi kúrò lọ́wọ́ àwọn ọ̀tá tó yí wọn ká. 
 
- 
                                        
- 
	                        
            
            Àìsáyà 31:8Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
- 
                            - 
                                        Ó máa sá lọ nítorí idà, Wọ́n sì máa fipá kó àwọn ọ̀dọ́kùnrin rẹ̀ ṣiṣẹ́. 
 
-