ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • Sáàmù 48:1-3
    Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
    • 48 Jèhófà tóbi, òun sì ni ìyìn yẹ jù lọ

      Ní ìlú Ọlọ́run wa, ní òkè mímọ́ rẹ̀.

       2 Gíga rẹ̀ rẹwà, ayọ̀ gbogbo ayé,+

      Òkè Síónì tó jìnnà réré ní àríwá,

      Ìlú Ọba Títóbi Lọ́lá.+

       3 Nínú àwọn ilé gogoro rẹ̀ tó láàbò,

      Ọlọ́run ti jẹ́ kí a mọ̀ pé òun ni ibi ààbò.*+

  • Sáàmù 87:1, 2
    Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
    • 87 Ìpìlẹ̀ ìlú rẹ̀ wà lórí àwọn òkè mímọ́.+

       2 Jèhófà nífẹ̀ẹ́ àwọn ẹnubodè Síónì  +

      Ju gbogbo àwọn àgọ́ Jékọ́bù lọ.

  • Sáàmù 132:13, 14
    Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
    • 13 Nítorí Jèhófà ti yan Síónì;+

      Ó fẹ́ kó jẹ́ ibùgbé rẹ̀, ó ní:+

      14 “Ibi ìsinmi mi títí láé nìyí;

      Ibí ni màá máa gbé,+ nítorí ohun tí mo fẹ́ nìyẹn.

Yorùbá Publications (1987-2025)
Jáde
Wọlé
  • Yorùbá
  • Fi Ráńṣẹ́
  • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
  • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
  • Àdéhùn Nípa Lílò
  • Òfin
  • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
  • JW.ORG
  • Wọlé
Fi Ráńṣẹ́