-
2 Àwọn Ọba 20:3Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
-
-
3 “Mo bẹ̀ ọ́, Jèhófà, jọ̀ọ́ rántí bí mo ṣe fi òtítọ́ àti gbogbo ọkàn mi rìn níwájú rẹ, ohun tó dáa ní ojú rẹ sì ni mo ṣe.”+ Hẹsikáyà sì bẹ̀rẹ̀ sí í sunkún pẹ̀rẹ̀pẹ̀rẹ̀.
-
-
Jeremáyà 11:20Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
-
-
Jẹ́ kí n rí ẹ̀san rẹ lára wọn,
Nítorí ọwọ́ rẹ ni mo fi ẹjọ́ mi lé.
-