- 
	                        
            
            2 Àwọn Ọba 20:3Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
- 
                            - 
                                        3 “Mo bẹ̀ ọ́, Jèhófà, jọ̀ọ́ rántí bí mo ṣe fi òtítọ́ àti gbogbo ọkàn mi rìn níwájú rẹ, ohun tó dáa ní ojú rẹ sì ni mo ṣe.”+ Hẹsikáyà sì bẹ̀rẹ̀ sí í sunkún pẹ̀rẹ̀pẹ̀rẹ̀. 
 
- 
                                        
- 
	                        
            
            Jeremáyà 11:20Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
- 
                            - 
                                        Jẹ́ kí n rí ẹ̀san rẹ lára wọn, Nítorí ọwọ́ rẹ ni mo fi ẹjọ́ mi lé. 
 
-