-
Jeremáyà 29:25Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
-
-
25 ‘Ohun tí Jèhófà Ọlọ́run àwọn ọmọ ogun, Ọlọ́run Ísírẹ́lì, sọ nìyí: “Nítorí pé o fi àwọn lẹ́tà ránṣẹ́ ní orúkọ rẹ sí gbogbo àwọn èèyàn tó wà ní Jerúsálẹ́mù àti sí Sefanáyà+ ọmọ Maaseáyà tó jẹ́ àlùfáà àti sí gbogbo àwọn àlùfáà, pé,
-