10 Ni mo bá sọ pé: “Áà, Jèhófà Olúwa Ọba Aláṣẹ! O ti tan àwọn èèyàn yìí+ àti Jerúsálẹ́mù jẹ pátápátá, o sọ pé, ‘Ẹ máa ní àlàáfíà,’+ nígbà tó jẹ́ pé idà ló wà lọ́rùn wa.”*
10 Gbogbo èyí jẹ́ torí pé wọ́n ti ṣi àwọn èèyàn mi lọ́nà, bí wọ́n ṣe ń sọ pé, “Àlàáfíà wà!” nígbà tí kò sí àlàáfíà.+ Tí wọ́n bá mọ ògiri tí kò lágbára, wọ́n á kùn ún ní ẹfun.’*+