ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • jy ojú ìwé 2-5
  • Ohun Tó Wà Nínú Ìwé Yìí

Kò sí fídíò kankan ní apá yìí.

Má bínú, fídíò yìí kò jáde.

  • Ohun Tó Wà Nínú Ìwé Yìí
  • Jésù—Ọ̀nà, Òtítọ́ Àti Ìyè
  • Ìsọ̀rí
  • APÁ 1​—KÍ JÉSÙ TÓ BẸ̀RẸ̀ IṢẸ́ ÒJÍṢẸ́ RẸ̀
  • APÁ 2​—ÌBẸ̀RẸ̀ IṢẸ́ ÒJÍṢẸ́ JÉSÙ
  • APÁ 3​—IṢẸ́ ÒJÍṢẸ́ TÓ TA YỌ TÍ JÉSÙ ṢE NÍ GÁLÍLÌ
  • APÁ 4​—IṢẸ́ ÒJÍṢẸ́ TÍ JÉSÙ PA DÀ ṢE NÍ JÙDÍÀ
  • APÁ 5​—IṢẸ́ ÒJÍṢẸ́ TÍ JÉSÙ PA DÀ ṢE NÍ ÌLÀ OÒRÙN JỌ́DÁNÌ
  • APÁ 6​—IṢẸ́ ÒJÍṢẸ́ TÍ JÉSÙ ṢE KẸ́YÌN
Jésù—Ọ̀nà, Òtítọ́ Àti Ìyè
jy ojú ìwé 2-5

Ohun Tó Wà Nínú Ìwé Yìí

OJÚ ÌWÉ APÁ ORÍ

APÁ 1​—KÍ JÉSÙ TÓ BẸ̀RẸ̀ IṢẸ́ ÒJÍṢẸ́ RẸ̀

10 1 Ìkéde Méjì Látọ̀dọ̀ Ọlọ́run

12 2 Wọ́n Pọ́n Jésù Lé Kí Wọ́n Tó Bí I

14 3 Wọ́n Bí Ẹni Tó Máa Ṣètò Ọ̀nà Sílẹ̀

16 4 Màríà Lóyún Láìṣègbéyàwó

18 5 Ìgbà Wo Ni Wọ́n Bí Jésù, Ibo sì Ni Wọ́n Bí I Sí?

20 6 Ọmọ Tí Ọlọ́run Ṣèlérí

22 7 Àwọn Awòràwọ̀ Wá Sọ́dọ̀ Jésù

24 8 Wọ́n Sá Lọ Mọ́ Ọba Burúkú Kan Lọ́wọ́

26 9 Ó Ń Dàgbà ní Násárẹ́tì

28 10 Jósẹ́fù àti Ìdílé Rẹ̀ Rìnrìn Àjò Lọ sí Jerúsálẹ́mù

30 11 Jòhánù Arinibọmi Ṣètò Ọ̀nà Sílẹ̀

APÁ 2​—ÌBẸ̀RẸ̀ IṢẸ́ ÒJÍṢẸ́ JÉSÙ

34 12 Jésù Ṣe Ìrìbọmi

36 13 Kẹ́kọ̀ọ́ Látinú Bí Jésù Ṣe Kojú Àdánwò

38 14 Jésù Bẹ̀rẹ̀ Sí Í Ní Ọmọ Ẹ̀yìn

40 15 Jésù Ṣe Iṣẹ́ Ìyanu Àkọ́kọ́

42 16 Jésù Ní Ìtara Fún Ìjọsìn Tòótọ́

44 17 Jésù Kọ́ Nikodémù Lẹ́kọ̀ọ́ Ní Òru

46 18 Jòhánù Ń Dín Kù, Àmọ́ Jésù Ń Pọ̀ Sí I

48 19 Jésù Kọ́ Obìnrin Ará Samáríà Kan Lẹ́kọ̀ọ́

APÁ 3​—IṢẸ́ ÒJÍṢẸ́ TÓ TA YỌ TÍ JÉSÙ ṢE NÍ GÁLÍLÌ

54 20 Iṣẹ́ Ìyanu Kejì ní Kánà

56 21 Jésù Lọ sí Sínágọ́gù Tó Wà ní Násárẹ́tì

58 22 Àwọn Ọmọ Ẹ̀yìn Mẹ́rin Di Apẹja Èèyàn

60 23 Jésù Ṣe Iṣẹ́ Ìyanu ní Kápánáúmù

62 24 Jésù Mú Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Rẹ̀ Gbòòrò Sí I ní Gálílì

64 25 Jésù Fàánú Hàn sí Adẹ́tẹ̀ Kan, Ó sì Wò Ó Sàn

66 26 “A Dárí Àwọn Ẹ̀ṣẹ̀ Rẹ Jì Ọ́”

68 27 Jésù Pe Mátíù

70 28 Kí Nìdí Tí Àwọn Ọmọlẹ́yìn Jésù Kò Fi Gbààwẹ̀?

72 29 Ṣé Èèyàn Lè Ṣe Ohun Tó Dáa Lọ́jọ́ Sábáàtì?

74 30 Bí Jésù Ṣe Jẹ́ sí Baba Rẹ̀

76 31 Wọ́n Já Ọkà Jẹ Lọ́jọ́ Sábáàtì

78 32 Kí Ló Bófin Mu ní Sábáàtì?

80 33 Jésù Mú Àsọtẹ́lẹ̀ Àìsáyà Ṣẹ

82 34 Jésù Yan Àwọn Àpọ́sítélì Méjìlá

84 35 Ìwàásù orí Òkè

92 36 Ọ̀gágun Kan Fi Hàn Pé Òun Nígbàgbọ́ Tó Lágbára

94 37 Jésù Jí Ọmọ Opó Kan Dìde

96 38 Jòhánù Fẹ́ Gbọ́rọ̀ Látẹnu Jésù

98 39 Jésù Dẹ́bi fún Ìran Aláìgbọràn

100 40 Ẹ̀kọ́ Nípa Ìdáríjì

102 41 Agbára Wo Ni Jésù Fi Ń Ṣe Iṣẹ́ Ìyanu?

104 42 Jésù Bá Àwọn Farisí Wí

106 43 Àwọn Àpèjúwe Nípa Ìjọba Ọlọ́run

112 44 Jésù Mú Kí Ìjì Dáwọ́ Dúró Lórí Òkun

114 45 Agbára Jésù Ju Ti Àwọn Ẹ̀mí Èṣù Lọ

116 46 Obìnrin Kan Rí Ìwòsàn Nígbà Tó Fọwọ́ Kan Aṣọ Jésù

118 47 Jésù Jí Ọmọbìnrin Kan Dìde!

120 48 Jésù Ṣe Iṣẹ́ Ìyanu, Àmọ́ Àwọn Ará Násárẹ́tì Kò Gbà Á Gbọ́

122 49 Ó Wàásù, Ó sì Dá Àwọn Àpọ́sítélì Lẹ́kọ̀ọ́ ní Gálílì

124 50 Wọ́n Ṣe Tán Láti Wàásù Láìka Àtakò Sí

126 51 Wọ́n Pa Èèyàn Níbi Ayẹyẹ Ọjọ́ Ìbí Kan

128 52 Ó Fi Ìwọ̀nba Búrẹ́dì àti Ẹja Bọ́ Ẹgbẹẹgbẹ̀rún Èèyàn

130 53 Alákòóso Kan Tó Láṣẹ Lórí Àwọn Nǹkan Àdáyébá

132 54 Jésù “Ni Oúnjẹ Ìyè”

134 55 Ọ̀rọ̀ Jésù Ya Ọ̀pọ̀ Èèyàn Lẹ́nu

136 56 Kí Ló Ń Sọni Di Aláìmọ́?

138 57 Jésù Wo Ọmọbìnrin Kan àti Adití Kan Sàn

140 58 Ó Mú Kí Búrẹ́dì Pọ̀, Ó sì Kìlọ̀ Nípa Ìwúkàrà

142 59 Ta Ni Ọmọ Èèyàn?

144 60 Ìran Ìyípadà Ológo

146 61 Jésù Wo Ọmọkùnrin Tí Ẹ̀mí Èṣù Ń Yọ Lẹ́nu Sàn

148 62 Ẹ̀kọ́ Pàtàkì Nípa Ẹ̀mí Ìrẹ̀lẹ̀

150 63 Méjì Lára Ìmọ̀ràn Jésù

152 64 Ìdí Tó Fi Yẹ Ká Máa Dárí Jini

154 65 Jésù Ń Kóni Nígbà Tó Ń Lọ sí Jerúsálẹ́mù

APÁ 4​—IṢẸ́ ÒJÍṢẸ́ TÍ JÉSÙ PA DÀ ṢE NÍ JÙDÍÀ

158 66 Ó Lọ sí Jerúsálẹ́mù Nígbà Àjọyọ̀ Àwọn Àgọ́ Ìjọsìn

160 67 “Èèyàn Kankan Ò Sọ̀rọ̀ Báyìí Rí”

162 68 Ọmọ Ọlọ́run Ni “Ìmọ́lẹ̀ Ayé”

164 69 Ṣé Ábúráhámù Ni Bàbá Wọn àbí Èṣù?

166 70 Jésù La Ojú Ọkùnrin Kan Tí Wọ́n Bí Ní Afọ́jú

168 71 Àwọn Farisí Gbọ́ Tẹnu Ọkùnrin Afọ́jú Náà

170 72 Jésù Rán Àádọ́rin (70) Ọmọ Ẹ̀yìn Jáde Lọ Wàásù

172 73 Ará Samáríà Kan Fàánú Hàn

174 74 Ẹ̀kọ́ Nípa Aájò Àlejò àti Àdúrà

176 75 Jésù Sọ Ohun Tó Ń Fúnni Láyọ̀

178 76 Farisí Kan Gba Jésù Lálejò

180 77 Jésù Sọ̀rọ̀ Nípa Ọrọ̀

182 78 Jésù Ní Kí Ìríjú Olóòótọ́ Náà Múra Sílẹ̀

184 79 Ìdí Táwọn Èèyàn Náà Fi Máa Pa Run

186 80 Olùṣọ́ Àgùntàn Àtàtà àti Agbo Àgùntàn

188 81 Ọ̀kan Ni Jésù àti Baba, Àmọ́ Jésù Kì Í Ṣe Ọlọ́run

APÁ 5​—IṢẸ́ ÒJÍṢẸ́ TÍ JÉSÙ PA DÀ ṢE NÍ ÌLÀ OÒRÙN JỌ́DÁNÌ

192 82 Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Jésù ní Pèríà

194 83 Àwọn Tí Ọlọ́run Pè Síbi Àsè Kan

196 84 Iṣẹ́ Kékeré Kọ́ Lẹ́nì Kan Máa Ṣe Kó Tó Lè Di Ọmọ Ẹ̀yìn

198 85 Àwọn Áńgẹ́lì Máa Ń Yọ̀ Tí Ẹlẹ́ṣẹ̀ Bá Ronú Pìwà Dà

200 86 Ọmọ Tó Sọ Nù Pa Dà Wálé

204 87 Múra Sílẹ̀, Kó O sì Jẹ́ Ọlọ́gbọ́n

206 88 Ọkùnrin Ọlọ́rọ̀ Kan àti Lásárù

210 89 Ó Ń Kọ́ni ní Pèríà Bó Ṣe Ń Lọ sí Jùdíà

212 90 “Àjíǹde àti Ìyè”

214 91 Jésù Jí Lásárù Dìde

216 92 Jésù Wo Adẹ́tẹ̀ Mẹ́wàá Sàn, Ọ̀kan Pa Dà Wá Dúpẹ́

218 93 Ọlọ́run Máa Ṣí Ọmọ Èèyàn Payá

220 94 Ohun Méjì Tó Ṣe Pàtàkì​—⁠Àdúrà àti Ẹ̀mí Ìrẹ̀lẹ̀

222 95 Jésù Sọ̀rọ̀ Nípa Ìkọ̀sílẹ̀, Ó sì Fìfẹ́ Hàn Sáwọn Ọmọdé

224 96 Jésù Dáhùn Ìbéèrè Ọ̀dọ́kùnrin Ọlọ́rọ̀ Kan

226 97 Àpèjúwe Àwọn Òṣìṣẹ́ Ọgbà Àjàrà

228 98 Àwọn Àpọ́sítélì Tún Ń Wá Ipò Ọlá

230 99 Jésù La Ojú Àwọn Afọ́jú, Ó sì Ran Sákéù Lọ́wọ́

232 100 Àpèjúwe Mínà Mẹ́wàá

APÁ 6​—IṢẸ́ ÒJÍṢẸ́ TÍ JÉSÙ ṢE KẸ́YÌN

236 101 Wọ́n Lọ Jẹun Nílé Símónì ní Bẹ́tánì

238 102 Ọba Gun Ọmọ Kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ Wọ Jerúsálẹ́mù

240 103 Jésù Fọ Tẹ́ńpìlì Mọ́ Lẹ́ẹ̀kan Sí I

242 104 Lẹ́yìn Táwọn Júù Gbọ́ Ohùn Ọlọ́run, Ṣé Wọ́n Gba Jésù Gbọ́?

244 105 Jésù Fi Igi Ọ̀pọ̀tọ́ Kan Kọ́ Wọn Lẹ́kọ̀ọ́ Nípa Ìgbàgbọ́

246 106 Àpèjúwe Méjì Nípa Ọgbà Àjàrà

248 107 Ọba Kan Pe Àwọn Èèyàn Wá Síbi Ayẹyẹ Ìgbéyàwó

250 108 Ìdáhùn Jésù Ò Jẹ́ Káwọn Ọ̀tá Rẹ̀ Rí I Mú

252 109 Ó Dẹ́bi Fáwọn Aṣáájú Ẹ̀sìn Tó Ń Ta Kò Ó

254 110 Ọjọ́ Tí Jésù Wá sí Tẹ́ńpìlì Kẹ́yìn

256 111 Àwọn Àpọ́sítélì Ní Kí Jésù Fún Àwọn Ní Àmì

260 112 Ẹ̀kọ́ Tí Àpèjúwe Wúńdíá Mẹ́wàá Kọ́ Wa

262 113 Ẹ̀kọ́ Tí Àpèjúwe Tálẹ́ńtì Kọ́ Wa

264 114 Kristi Máa Ṣèdájọ́ Àgùntàn àti Ewúrẹ́

266 115 Ìrékọjá Tí Jésù Máa Ṣe Kẹ́yìn Ń Sún Mọ́lé

268 116 Jésù Kọ́ Wọn Lẹ́mìí Ìrẹ̀lẹ̀ Níbi Ìrékọjá Tó Ṣe Kẹ́yìn

270 117 Oúnjẹ Alẹ́ Olúwa

272 118 Wọ́n Jiyàn Nípa Ẹni Tó Tóbi Jù

274 119 Jésù Ni Ọ̀nà, Òtítọ́ Àti Ìyè

276 120 Béèyàn Ṣe Lè Dà Bí Ẹ̀ka Tó ń so Èso, Kó Sì Di Ọ̀rẹ́ Jésù

278 121 “Ẹ Mọ́kàn Le! Mo Ti Ṣẹ́gun Ayé”

280 122 Àdúrà Tí Jésù Gbà Kẹ́yìn Ní Yàrá Tó Wà Lókè

282 123 Jésù Gbàdúrà Nígbà Tí Ẹ̀dùn Ọkàn Bá A

284 124 Júdásì Da Jésù, Wọ́n Sì Fàṣẹ Ọba Mú Jésù

286 125 Wọ́n Mú Jésù Lọ Sọ́dọ̀ Ánásì Àti Káyáfà

288 126 Pétérù Sẹ́ Jésù Nílé Káyáfà

290 127 Jésù Jẹ́jọ́ Níwájú Sàhẹ́ndìrìn Àti Pílátù

292 128 Pílátù Àti Hẹ́rọ́dù Rí I Pé Jésù Ò Jẹ̀bi

294 129 Pílátù Sọ Pé: “Ẹ Wò Ó! Ọkùnrin Náà Nìyí!”

296 130 Ó Fa Jésù Lé Wọn Lọ́wọ́ Kí Wọ́n Lè Lọ Pa Á

298 131 Ọba Kan ń jìyà Láìṣẹ̀ Lórí Òpó Igi

300 132 “Ó Dájú Pé Ọmọ Ọlọ́run Ni Ọkùnrin Yìí”

302 133 Wọ́n Ṣètò Òkú Jésù, Wọ́n Sì Lọ Sin Ín

304 134 Ọlọ́run Ti Jí Jésù Dìde, Ibojì Rẹ̀ Sì Ti Ṣófo!

306 135 Jésù Fara Han Ọ̀pọ̀ Èèyàn Lẹ́yìn Tó Jíǹde

308 136 Ohun Tó Ṣẹlẹ̀ Létíkun Gálílì

310 137 Ọ̀pọ̀ Èèyàn Ló Rí Jésù Ṣáájú Ọjọ́ Pẹ́ńtíkọ́sì

312 138 Kristi Wà Lọ́wọ́ Ọ̀tún Ọlọ́run

314 139 Jésù Parí Iṣẹ́ Rẹ̀, Ó Sì Máa Sọ Ayé Di Párádísè

    Yorùbá Publications (1987-2025)
    Jáde
    Wọlé
    • Yorùbá
    • Fi Ráńṣẹ́
    • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
    • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
    • Àdéhùn Nípa Lílò
    • Òfin
    • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
    • JW.ORG
    • Wọlé
    Fi Ráńṣẹ́