ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • lfb ojú ìwé 4-5
  • Ohun Tó Wà Nínú Ìwé Yìí

Kò sí fídíò kankan ní apá yìí.

Má bínú, fídíò yìí kò jáde.

  • Ohun Tó Wà Nínú Ìwé Yìí
  • Àwọn Ẹ̀kọ́ Tó O Lè Kọ́ Látinú Bíbélì
Àwọn Ẹ̀kọ́ Tó O Lè Kọ́ Látinú Bíbélì
lfb ojú ìwé 4-5

Ohun Tó Wà Nínú Ìwé Yìí

Ẹ̀KỌ́

Ọ̀rọ̀ Ìṣáájú fún Apá 1​—Ìṣẹ̀dá

1 Ọlọ́run Dá Ọ̀run àti Ayé

2 Ọlọ́run Dá Ọkùnrin àti Obìnrin Àkọ́kọ́

Ọ̀rọ̀ Ìṣáájú fún Apá 2​—Látìgbà Ayé Ádámù sí Ìgbà Àkúnya Omi

3 Ádámù àti Éfà Ṣàìgbọràn sí Ọlọ́run

4 Kéènì Bínú Pa Àbúrò Rẹ̀

5 Nóà Kan Áàkì

6 Èèyàn Mẹ́jọ La Ìparun Já

Ọ̀rọ̀ Ìṣáájú fún Apá 3​—Látìgbà Ìkún Omi sí Ìgbà Ayé Jékọ́bù

7 Ilé Gogoro Bábélì

8 Ábúráhámù àti Sérà Ṣègbọràn sí Ọlọ́run

9 Sérà Bímọ Nígbà Tó Darúgbó!

10 Ẹ Rántí Aya Lọ́ọ̀tì

11 Ọlọ́run Dán Ìgbàgbọ́ Ábúráhámù Wò

12 Jékọ́bù Rí Ogún Gbà

13 Jékọ́bù àti Ísọ̀ Parí Ìjà Wọn

Ọ̀rọ̀ Ìṣáájú fún Apá 4​—Látìgbà Ayé Jósẹ́fù sí Òkun Pupa

14 Ẹrú Tó Ṣègbọràn sí Ọlọ́run

15 Jèhófà Ò Gbàgbé Jósẹ́fù

16 Ta Ni Jóòbù?

17 Mósè Pinnu Láti Jọ́sìn Jèhófà

18 Iná Ń Jó Lára Igi Kékeré Kan

19 Ìyọnu Mẹ́ta Àkọ́kọ́

20 Àwọn Ìyọnu Mẹ́fà Tó Tẹ̀ Lé E

21 Ìyọnu Kẹwàá

22 Iṣẹ́ Ìyanu ní Òkun Pupa

Ọ̀rọ̀ Ìṣáájú fún Apá 5​—Nínú Aginjù

23 Wọ́n Ṣèlérí fún Jèhófà

24 Wọn Ò Mú Ìlérí Wọn Ṣẹ

25 Wọ́n Kọ́ Àgọ́ Ìjọsìn

26 Àwọn Amí Méjìlá

27 Wọ́n Ta Ko Jèhófà

28 Kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ Báláámù Sọ̀rọ̀

Ọ̀rọ̀ Ìṣáájú fún Apá 6​—Àwọn Onídàájọ́

29 Jèhófà Yan Jóṣúà

30 Ráhábù Fi Àwọn Amí Pa Mọ́

31 Jóṣúà àti Àwọn Ará Gíbéónì

32 Aṣáájú Tuntun àti Obìnrin Onígboyà Méjì

33 Rúùtù àti Náómì

34 Gídíónì Ṣẹ́gun Àwọn Ará Mídíánì

35 Hánà Gbàdúrà Pé Kí Ọlọ́run Fún Òun ní Ọmọkùnrin

36 Ìlérí Tí Jẹ́fútà Ṣe

37 Jèhófà Bá Sámúẹ́lì Sọ̀rọ̀

38 Jèhófà Sọ Sámúsìn Di Alágbára

Ọ̀rọ̀ Ìṣáájú fún Apá 7​—Dáfídì àti Sọ́ọ̀lù

39 Ọba Àkọ́kọ́ ní Ísírẹ́lì

40 Dáfídì àti Gòláyátì

41 Dáfídì àti Sọ́ọ̀lù

42 Jónátánì Nígboyà, Ó sì Jẹ́ Adúrótini

43 Ọba Dáfídì Dẹ́ṣẹ̀

Ọ̀rọ̀ Ìṣáájú fún Apá 8​—Látìgbà Ayé Sólómọ́nì sí Ìgbà Ayé Èlíjà

44 Wọ́n Kọ́ Tẹ́ńpìlì fún Jèhófà

45 Ìjọba Ísírẹ́lì Pín sí Méjì

46 Ìṣẹ̀lẹ̀ Kan Lórí Òkè Kámẹ́lì

47 Jèhófà Fún Èlíjà Lókun

48 Ọmọkùnrin Opó Kan Jíǹde

49 Ọlọ́run Fìyà Jẹ Ayaba Kan Tó Burú Gan-an

50 Jèhófà Gbèjà Jèhóṣáfátì

Ọ̀rọ̀ Ìṣáájú fún Apá 9​—Látìgbà Ayé Èlíṣà sí Ìgbà Ayé Jòsáyà

51 Jagunjagun àti Ọmọbìnrin Kékeré Kan

52 Àwọn Ọmọ Ogun Jèhófà

53 Jèhóádà Nígboyà

54 Jèhófà Ní Sùúrù fún Jónà

55 Áńgẹ́lì Jèhófà Dáàbò Bo Hẹsikáyà

56 Jòsáyà Fẹ́ràn Òfin Ọlọ́run

Ọ̀rọ̀ Ìṣáájú fún Apá 10​—Látìgbà Ayé Jeremáyà sí Ìgbà Ayé Nehemáyà

57 Jèhófà Rán Jeremáyà Pé Kó Lọ Wàásù

58 Wọ́n Pa Jerúsálẹ́mù Run

59 Ọ̀dọ́kùnrin Mẹ́rin Ṣègbọràn sí Jèhófà

60 Ìjọba Kan Tó Máa Wà Títí Láé

61 Wọn Ò Tẹrí Ba

62 Ìjọba Kan Tó Dà Bí Igi Ńlá

63 Ọ̀rọ̀ Tó Hàn Lára Ògiri

64 Wọ́n Ju Dáníẹ́lì Sínú Ihò Kìnnìún

65 Ẹ́sítà Gba Àwọn Èèyàn Ẹ̀ Nínú Ewu

66 Ẹ́sírà Kọ́ Àwọn Èèyàn ní Òfin Ọlọ́run

67 Ògiri Jerúsálẹ́mù

Ọ̀rọ̀ Ìṣáájú fún Apá 11​—Jòhánù Arinibọmi àti Jésù

68 Èlísábẹ́tì Bí Ọmọ Kan

69 Áńgẹ́lì Gébúrẹ́lì Lọ Sọ́dọ̀ Màríà

70 Àwọn Áńgẹ́lì Kéde Pé Wọ́n Ti Bí Jésù

71 Jèhófà Dáàbò Bo Jésù

72 Ìgbà Tí Jésù Wà Lọ́mọdé

73 Jòhánù Múra Àwọn Èèyàn Sílẹ̀

Ọ̀rọ̀ Ìṣáájú fún Apá 12​—Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Jésù

74 Jésù Di Mèsáyà

75 Èṣù Dán Jésù Wò

76 Jésù Lé Àwọn Tó Ń Tajà Nínú Tẹ́ńpìlì

77 Obìnrin Kan Wá Pọn Omi Nínú Kànga

78 Jésù Wàásù Nípa Ìjọba Ọlọ́run

79 Jésù Ṣe Ọ̀pọ̀ Iṣẹ́ Ìyanu

80 Jésù Yan Àwọn Àpọ́sítélì Méjìlá

81 Ìwàásù Orí Òkè

82 Jésù Kọ́ Àwọn Ọmọ Ẹ̀yìn Ẹ̀ Bí Wọ́n Á Ṣe Máa Gbàdúrà

83 Jésù Fún Ọ̀pọ̀ Èèyàn Lóúnjẹ

84 Jésù Rìn Lórí Omi

85 Jésù Wo Ẹnì Kan Sàn Lọ́jọ́ Sábáàtì

86 Jésù Jí Lásárù Dìde

Ọ̀rọ̀ Ìṣáájú fún Apá 13​—Ọ̀sẹ̀ Tí Jésù Lò Kẹ́yìn Láyé

87 Oúnjẹ Alẹ́ Olúwa

88 Wọ́n Mú Jésù

89 Pétérù Sọ Pé Òun Ò Mọ Jésù Rí

90 Wọ́n Pa Jésù ní Gọ́gọ́tà

91 Jésù Jíǹde

92 Jésù Fara Han Àwọn Apẹja

93 Jésù Pa Dà sí Ọ̀run

Ọ̀rọ̀ Ìṣáájú fún Apá 14​—Ẹ̀sìn Kristẹni Tàn Káàkiri

94 Àwọn Ọmọ Ẹ̀yìn Jésù Gba Ẹ̀mí Mímọ́

95 Kò Sóhun Tó Lè Dá Wọn Dúró

96 Jésù Yan Sọ́ọ̀lù

97 Kọ̀nílíù Gba Ẹ̀mí Mímọ́

98 Ẹ̀sìn Kristẹni Dé Ọ̀pọ̀ Orílẹ̀-Èdè

99 Ẹ̀ṣọ́ Ọgbà Ẹ̀wọ̀n Kan Gbọ́ Ọ̀rọ̀ Ọlọ́run

100 Pọ́ọ̀lù àti Tímótì

101 Wọ́n Gbé Pọ́ọ̀lù Lọ sí Róòmù

102 Ìran Tí Jòhánù Rí

103 “Kí Ìjọba Rẹ Dé”

    Yorùbá Publications (1987-2025)
    Jáde
    Wọlé
    • Yorùbá
    • Fi Ráńṣẹ́
    • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
    • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
    • Àdéhùn Nípa Lílò
    • Òfin
    • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
    • JW.ORG
    • Wọlé
    Fi Ráńṣẹ́