ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • w95 12/15 ojú ìwé 31
  • Atọ́ka Àwọn Kókó Ẹ̀kọ́ Ilé-ìṣọ́nà 1995

Kò sí fídíò kankan ní apá yìí.

Má bínú, fídíò yìí kò jáde.

  • Atọ́ka Àwọn Kókó Ẹ̀kọ́ Ilé-ìṣọ́nà 1995
  • Ilé-Ìṣọ́nà Tí Ń Kéde Ìjọba Jehofa—1995
  • Ìsọ̀rí
  • ÀWỌN ẸLẸ́RÌÍ JEHOFA
  • ÀWỌN OLÙPÒKÌKÍ ÌJỌBA RÒYÌN
  • BIBELI
  • ÌBÉÈRÈ LÁTI ỌWỌ́ ÀWỌN ÒǸKÀWÉ
  • ÌGBÉSÍ AYÉ ÀTI ÀNÍMỌ́ KRISTIAN
  • ÌTÀN ÌGBÉSÍ AYÉ
  • JEHOFA
  • JESU KRISTI
  • LÁJORÍ Ọ̀RỌ̀ Ẹ̀KỌ́ FÚN ÌKẸ́KỌ̀Ọ́
  • Ọ̀KAN-Ò-JỌ̀KAN
Ilé-Ìṣọ́nà Tí Ń Kéde Ìjọba Jehofa—1995
w95 12/15 ojú ìwé 31

Atọ́ka Àwọn Kókó Ẹ̀kọ́ Ilé-ìṣọ́nà 1995

Tí Ń tọ́ka Ọjọ́ Ìtẹ̀jáde Tí Ọ̀rọ̀ Ẹ̀kọ́ Fara Hàn

ÀWỌN ẸLẸ́RÌÍ JEHOFA

Àpéjọpọ̀ Àgbègbè “Àwọn Onídùnnú-Ayọ̀ Olùyìn,” 10/15

Àpéjọpọ̀ Àgbègbè “Àwọn Olùbẹ̀rù Ọlọrun,” 1/15

Ateni, Griki, 10/15

A Dá Ẹjọ́ Tí A Pe Àwọn Ẹlẹ́rìí Jehofa (Griki), 12/15

Brazil, 7/15

Dominican Republic, 2/15

Gbọ̀ngàn Ìjọba ní Niue, 12/15

Gígun Òkè-Ńlá Tí Ó Ga Ju Ti Àwọn Himalaya Lọ (Nepal), 6/15

‘Ì bá Ṣe Pé Gbogbo Ènìyàn Dà Bí Wọn Ni!’ 9/1

“Ibo Ni Owó Náà Ti Ń Wá?” 12/1

Ìkẹ́kọ̀ọ́yege Gilead, 6/1, 12/1

India, 9/15

Kò Sí Ìfẹ̀yìntì fún Wa! (Japan), 3/15

“Láti Ẹnu Àwọn Ìkókó,” 1/1

“Mo Ṣe Iyebíye Lójú Jehofa!” 12/15

New Zealand, 11/15

Puerto Rico, 1/15

Singapore Tẹ Òmìnira Ìjọsìn Mọ́lẹ̀, 10/1

Sri Lanka, 8/15

Sweden, 5/15

‘Títa Iyọ̀’ ní Mozambique, 4/15

Zambia, 3/15

ÀWỌN OLÙPÒKÌKÍ ÌJỌBA RÒYÌN

1/1, 2/1, 3/1, 4/1, 5/1, 7/1, 8/1, 9/1, 11/1, 12/1

BIBELI

Báwo Ni Bibeli kan Ti Níyelórí Tó? 3/15

Ìgbà Tí Wọ́n Ń Kà Á àti Bí Wọ́n Ṣe Ń Jàǹfààní, 5/1

Kí Ni Ìwé Àwọn Masorete? 5/15

“Májẹ̀mú Láéláé” Tàbí “Ìwé Mímọ́ Lédè Heberu,” 3/1

New World Translation Wú Ọ̀mọ̀wé Akẹ́kọ̀ọ́jinlẹ̀ kan Lórí, 4/15

ÌBÉÈRÈ LÁTI ỌWỌ́ ÀWỌN ÒǸKÀWÉ

“Awọn àgùtàn mìíràn” àti “ogunlọ́gọ̀ ńlá” ha yàtọ̀ bí? 4/15

Àwọn wo ni àwọn Filistini? 2/1

“Ẹ̀mí” nínú Galatia 6:8, 6/15

“Ìran” (1 Pe 2:9; Mt 24:34), 11/1

Ìṣarasíhùwà tí ó yẹ kí a fi hàn nígbà batisí, 4/1

Jesu ha jẹ́ àlùfáà àgbà fún “awọn àgùtàn mìíràn” nísinsìnyí bí? 6/1

‘Kì í ṣe púpọ̀ ni ó níláti di olùkọ́’ (Jak 3:1), 9/15

“Kò sí ìbẹ̀rù ninu ìfẹ́” (1 Joh 4:18), “ẹ máa bẹ̀rù Ọlọrun” (1 Pe 2:17), 8/1

Maria ha ti lóyún nígbà tí ó bẹ Elisabeti wò bí? 7/15

“Orúkọ tí ó lékè gbogbo orúkọ mìíràn” (Flp 2:9), 11/15

Ọlọrun ha ṣojúsàájú níwọ̀n bí gbogbo àwọn ẹgbẹ́ olùṣàkóso ìjímìjí ti jẹ́ Júù bí? 7/1

ÌGBÉSÍ AYÉ ÀTI ÀNÍMỌ́ KRISTIAN

Àwọn Ìdílé Olùṣèfẹ́ Ọlọrun ní Ìgbà Àtijọ́, 9/15

Báwo Ni O Ṣe Lè Mú Àdúrà Rẹ Sunwọ̀n Síi? 3/15

Bí Àwọn Kristian Ṣe Ń Kojú Ẹ̀gàn ní Gbangba, 4/1

Dènà Àwọn Àṣà Àtọwọ́dọ́wọ́ Tí Kò Wu Ọlọrun! 8/15

Èrè Ìtẹpẹlẹmọ́, 8/1

Ẹ̀bi Ta Ni? 2/1

Ẹ̀kọ́ Àríkọ́gbọ́n Nípa Bí A Ṣe Lè Bójútó Ìṣòro, 2/15

‘Ẹ Má Ṣe Fi Àìdọ́gba So Pọ̀ Mọ́ra Sábẹ́ Àjàgà,’ 11/15

Ẹ̀mí Fífúnni, 12/15

Ìgbọràn Oníwà-bí-Ọlọ́run Nínú Ìdílé Tí Ó Yapa Níti Ìsìn, 6/1

Ìtùnú fún Àwọn Tí Wọ́n Ní “Ọkàn Rírẹ̀wẹ̀sì,” 11/1

Ìwọ́ Ha Lè Mú Ìfòyemọ̀ Dàgbà Sí i Bí? 9/1

Ìwọ Yóò Ha Fẹ́ Òwú Àtùpà Tí Ń Jó Lọ́úlọ́ú Pa Bí? 11/15

Ìyọlẹ́gbẹ́—Ìpèsè Onífẹ̀ẹ́ Ha Ni Bí? 7/15

Òdodo Ní Ń Gbé Orílẹ̀-Èdè Lékè, 12/15

O Ha Ti Fún Ẹnikẹ́ni Ní Ìṣírí Láìpẹ́ Yìí Bí? 1/15

O Lè Borí Àwọn Ìdènà Wọ̀nyí! 7/15

Pa Ìwàtítọ́ Mọ́ Kí O Sì Wàláàyè! 1/1

Pa Òye Ìjẹ́kánjúkánjú Rẹ Mọ́, 10/1

Pípinnu Àìlera, Ìwà Burúkú, àti Ìrònúpìwàdà, 1/1

Sùúrù—Èéṣe Tí Ó Fi Ṣọ̀wọ́n Tóbẹ́ẹ̀? 6/15

Ṣọ́ra fún Jíjẹ́ Olódodo Lójú Ara Ẹni! 10/15

Wíwà Láìlọ́kọ Láìláya Ní Àkókò Tí Ọrọ̀-Ajé Kò Rọgbọ, 6/15

ÌTÀN ÌGBÉSÍ AYÉ

A Fún Wa Ní Péálì Tí Ìníyelórí Rẹ̀ Ga (R. Gunther), 6/1

‘A Gbé Mi Ṣánlẹ̀, Ṣùgbọ́n A Kò Pa Mí Run’ (U. Helgesson), 11/1

Ẹni Ọgọ́rùn-ún Ọdún Tí Ń Ta Kébékébé (R. Mitchell), 12/1

“Ìfẹ́ Kì í Kùnà Láé,” (S. Ladeṣuyi), 9/1

Ìforítì Ń Yọrí sí Ìtẹ̀síwájú (J. Maglovsky), 5/1

Ìpinnu Mi Láti Tẹ̀síwájú Dé Ìdàgbàdénú (C. Dochow), 4/1

Mo Dánìkan Wà Ṣùgbọ́n A Kò Pa Mí Tì (A. Lewis), 7/1

‘Níwọ̀n Bí A Ti Ní Iṣẹ́-Òjíṣẹ́ Yìí, Àwa Kò Juwọ́sílẹ̀’(R. Taylor), 2/1

Ogún Wa Nípa Tẹ̀mí Tí Ó Dọ́ṣọ̀ (F. Smith), 8/1

Ohun Dídára Jùlọ Tí Mo Lè Lo Ìgbésí-Ayé Mi Fún (B. Anderson) 3/1

Ohun Ìṣúra Tí Kò Ṣeé Díyelé Tí A Níláti Ṣàjọpín (G. Malaspina), 1/1

Títẹ̀ Lé Ipasẹ̀ Àwọn Òbí Mi (H. Padgett), 10/1

JEHOFA

Àwọn Ẹyọ-Owó Tí Ó Ní Orúkọ Ọlọrun, 5/15

JESU KRISTI

A Ha Dá Iyèméjì Nípa Jesu Láre Bí? 8/15

Àwọn Iṣẹ́ Ìyanu Jesu, 3/1

LÁJORÍ Ọ̀RỌ̀ Ẹ̀KỌ́ FÚN ÌKẸ́KỌ̀Ọ́

A Gbà Wọ́n Là Láti Inú “Ìran Burúkú,” 11/1

“Àjàgà Mi Jẹ́ Ti Inúrere Ẹrù Mi Sì Fúyẹ́,” 8/15

Àjíǹde Àwọn Olódodo Yóò Wà, 2/15

Àkókò Láti Wà Lójúfò, 11/1

A Ń Kọ́ Wa Láti Ọ̀dọ̀ Jehofa Títí Dòní, 8/1

A Pa Wọn Mọ́ Láàyè La Ìpọ́njú Ńlá Já, 2/15

Àwọn Àǹfààní Bíbẹ̀rù Ọlọrun Tòótọ́, 3/15

Àwọn Ẹlẹ́rìí ní Ìlòdìsí Àwọn Ọlọrun Èké, 9/1

Àwọn Ìbùyẹ̀rì Ìmọ́lẹ̀ ní Àkókò Àwọn Aposteli, 5/15

Àwọn Ìbùyẹ̀rì Ìmọ́lẹ̀—Ńlá àti Kékeré (Apá 1 àti 2), 5/15

Àwọn Ìlú Ààbò—Ìpèsè Aláàánú Ọlọrun, 11/15

Àwọn Kristian Ẹlẹ́rìí fún Ipò Ọba-Aláṣẹ Àtọ̀runwá, 9/1

Àwọn Kristian Ẹlẹ́rìí Tí Wọ́n Ní Ẹ̀tọ́ Gẹ́gẹ́ Bí Aráàlú Ní Ọ̀run, 7/1

Àwọn Kristian Obìnrin Yẹ fún Ọlá àti Ọ̀wọ̀, 7/15

Àwọn Olùgbé Papọ̀ ní “Ilẹ̀” Tí A Múpadàbọ̀sípò, 7/1

Àwọn Onídùnnú-Ayọ̀ “Olùṣe Ọ̀rọ̀ Náà,” 12/15

Báwo Ni Ìwọ Yóò Ṣe Dúró Níwájú Ìtẹ́ Ìdájọ́? 10/15

Bí Ó Tilẹ̀ Jẹ́ Pé A Ń Kẹ́dùn, A Kò Wà Láìní Ìrètí, 6/1

Dúró sí “Ìlú Ààbò” Kí O Sì Wà Láàyè! 11/15

Èé Ṣe Tí Ó Fi Yẹ Kí A Bẹ̀rù Ọlọrun Tòótọ́ Náà Nísinsìnyí? 10/15

Ẹ Máa Ru Ara Yín Lọ́kàn Sókè sí Ìfẹ́ àti sí Àwọn Iṣẹ́ Àtàtà—Báwo? 4/1

Ẹ Má Ṣe Juwọ́ Sílẹ̀! 12/1

Ẹ Ṣe Iyebíye Lójú Ọlọrun! 4/1

Ẹ̀yin Òbí àti Ẹ̀yin Ọmọ: Ẹ Fi Ọlọrun sí Ipò Kìíní! 10/1

Gbígbé Ní Ìbámu Pẹ̀lú Ìyàsímímọ́ Wa “Lati Ọjọ́ Dé Ọjọ́” 3/1

Ìdùnnú-Ayọ̀ Jehofa Ni Odi-Agbára Wa, 1/15

Ìfẹ́ Ń Ṣẹ́gun Owú Tí Kò Tọ́, 9/15

Ìkésíni Onífẹ̀ẹ́ sí Àwọn Tí Àárẹ̀ Mú, 8/15

Ipa-Iṣẹ́ Oníyì ti Àwọn Obìnrin Láàárín Àwọn Ìránṣẹ́ Ọlọrun ní Ìjímìjí, 7/15

Ìrẹ̀lẹ́kún Láti Ọ̀dọ̀ “Ọlọrun Ìtùnú Gbogbo,” 6/1

“Israeli Ọlọrun” àti “Ogunlọ́gọ̀ Ńlá,” 7/1

“Iṣẹ́-Ìsìn Mímọ́-Ọlọ́wọ̀ Pẹ̀lú Agbára Ìmọnúúrò Yín,” 6/15

Ìyàsímímọ́—Fún Ta Ni? 3/1

Jehofa Ń Fi Agbára fún Àwọn Aláàárẹ̀, 12/1

Jehofa—Ọlọrun Tí Ń Kọ́ni, 8/1

Jíjàǹfààní Láti Inú Bibeli Kíkà Lójoojúmọ́, 5/1

Jíjowú fún Ìjọsìn Mímọ́ Gaara ti Jehofa, 9/15

Kíkọ́ Láti Rí Ìgbádùn Nínú Ìbẹ̀rù Jehofa, 3/15

Kí Ní Ń Sún Ọ Láti Ṣiṣẹ́sin Ọlọrun? 6/15

“Má Bẹ̀rù, Agbo Kékeré,” 2/15

Ogunlọ́gọ̀ Ńlá ti Àwọn Olùjọsìn Tòótọ́—Níbo Ni Wọ́n Ti Wá? 2/1

Ogunlọ́gọ̀ Ńlá Tí Ń Ṣe Iṣẹ́-Ìsìn Mímọ́-Ọlọ́wọ̀, 2/1

Orílẹ̀-Èdè Náà Tí Ń Pa Ìwàtítọ́ Mọ́, 1/1

Ọjọ́ Jehofa Tí Ń Múnikún-fún-Ẹ̀rù Súnmọ́lé, 4/15

Ọjọ́ Ọ̀la Wo Ni Ó Wà fún Àwọn Àgùntàn àti Ewúrẹ́? 10/15

Ọjọ́ Tí Ń “Jó Bí Iná Ìléru,” 4/15

Ọlọrun Ha Gbapò Kìíní Nínú Ìdílé Rẹ Bí? 10/1

Ṣiṣẹ́sin Jehofa Pẹ̀lú Ìdùnnú-Ayọ̀ Ọkàn-Àyà, 1/15

Tẹ́wọ́gba Bibeli Nítorí Ohun Tí Ó Jẹ́ Nítòótọ́, 5/1

Wọ́n ‘Ṣe Bẹ́ẹ̀ Gẹ́lẹ́,’ 12/15

Yíyọ Ayọ̀ Ìṣẹ́gun Lórí Satani àti Iṣẹ́ Rẹ̀, 1/1

Ọ̀KAN-Ò-JỌ̀KAN

Àádọ́ta Ọdún Ìsapá Òtúbáńtẹ́ (Ìparapọ̀ Àwọn Orílẹ̀-Èdè), 10/1

Ààtò Àṣà Aláìnítumọ̀ Kẹ̀? (Ìjẹ́wọ́), 9/15

A Tún Ìfàjẹ̀sínilára Dàrò, 8/1

Àwọn Abo-Ọlọ́run Ogun àti Afúnnilọ́mọ, 11/15

Àwọn Áńgẹ́lì, 11/1

Àwọn Ará Ammoni—Àwọn Afibi-San-Oore, 12/15

Àwọn Cathar—Kristian Ajẹ́rìíkú Ha Ni Wọ́n Bí? 9/1

Àwọn Karaite àti Bí Wọ́n Ṣe Wá Òtítọ́ Kiri, 7/15

Àwọn Masorete, 9/15

Àwọn Obìnrin Káàkiri Ayé, 6/15

Àwọn Olùṣàkóso ní Ilẹ̀-Àkóso Ẹ̀mí, 7/15

Àyànmọ́, 2/15

Ayé Kan Láìsí Ìwà Ìbàjẹ́, 6/1

Ayé kan Láìsí Ogun—Nígbà Wo? 10/1

Báwo Ni Ìwàláàyè Ṣe Ṣeyebíye fún Ọ Tó? 1/15

Ẹtì Àwọn Ẹlẹ́kọ̀ọ́ Ìsìn (ọkàn àìleèkú), 3/1

Ìbẹ̀rù—Ó Wọ́ Pọ̀ Nísinsìnyí Ṣùgbọ́n Kì Yóò Jẹ́ Títí Láé! 10/15

Ìbẹ̀rù—Ọ̀rẹ́ Ni Tàbí Ọ̀tá? 10/15

Ìgbà Tí Ó Sàn Jù Ń Bẹ Níwájú, 8/1

Ìgbésí Ayé Dídára Jù Láìpẹ́! 11/15

Ìkórìíra Yóò Ha Dópin Láé Bí? 6/15

Iná Wọn Kò Kú, 11/15

Ìsìn—Ọ̀rọ̀ Àìgbọdọ̀sọ Ha Ni Bí? 4/1

Ìsìn Rẹ—Ohun Tí O Kò Gbọ́dọ̀ Kúrò Nínú Rẹ̀ Ha Ni Bí? 2/1

Ìwàláàyè Titun Yóò Wà fún Àwọn Babańlá Wa, 5/15

Ìwọ Yóò Ha Yin Jehofa Bí? 3/15

Ìwúkàrà Awọn Farisi ati Awọn Sadusi, 3/15

“Kí Ni Òtítọ́?” 7/1

Kí Ni Òwò Rẹ Yóò Ná Ọ? 5/1

Maimonides—Ọkùnrin Tí Ó Mú Ìsìn Júù Ṣe Kedere, 3/1

Nígbà Tí Ẹnikẹ́ni Kì Yóò Tòṣì Mọ́, 5/1

Nígbà Tí Òfin Àtọwọ́dọ́wọ́ Bá Forí Gbárí Pẹ̀lú Òtítọ́, 12/1

Nígbà Wo Ni Ìbẹ̀rù Yóò Dópin? 8/15

Ó Gba Ìtọ́sọ́nà Àtọ̀runwá (Josefu, Bàbá Alágbàtọ́ Jesu), 1/15

Ojú Ọ̀nà sí Òmìnira, 9/1

Òkè Tí Ń “Rìn” (Ireland), 4/15

Onílara Ẹ̀dá, 9/15

Òǹtẹ̀wé Tí Ó Tayọlọ́lá (Robert Estienne), 4/15

Òun Ni Ẹni Tí A Rán Ṣáájú Messia Náà (Johannu Oníbatisí), 5/15

Owú, 9/15

Owú Fẹ́rẹ̀ẹ́ Ba Ìgbésí Ayé Mi Jẹ́, 9/15

Ọgbọ́n Ìhùmọ̀—Ẹ̀bùn Láti Ọwọ́ Ọlọrun, 2/1

Ọlọrun Ha Ti Pinnu Kádàrá Wa Tẹ́lẹ̀ Bí? 2/15

Ọlọrun Ni Ó Ha Ń Ṣàkóso Ayé Bí? 7/15

Ọwọ́ Ha Lè Tó Òtítọ́ Ìsìn Bí? 4/15

William Tyndale—Ọkùnrin Aríranjìnnà, 11/15

    Yorùbá Publications (1987-2025)
    Jáde
    Wọlé
    • Yorùbá
    • Fi Ráńṣẹ́
    • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
    • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
    • Àdéhùn Nípa Lílò
    • Òfin
    • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
    • JW.ORG
    • Wọlé
    Fi Ráńṣẹ́