ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • mwb23 November ojú ìwé 6
  • Owó Kọ́ Ló Ń Mú Kéèyàn Jẹ́ Olódodo

Kò sí fídíò kankan ní apá yìí.

Má bínú, fídíò yìí kò jáde.

  • Owó Kọ́ Ló Ń Mú Kéèyàn Jẹ́ Olódodo
  • Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Kristẹni—Ìwé Ìpàdé—2023
  • Àpilẹ̀kọ Míì Tó Jọ ọ́
  • Inú Jèhófà Máa Ń Dùn Tá A Bá Gbàdúrà Fáwọn Ẹlòmíì
    Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Àwa Kristẹni​—Ìwé Ìpàdé (2016)
  • Jobu Lo Ìfaradà—Àwa Pẹ̀lú Lè Ṣe Bẹ́ẹ̀!
    Ilé-Ìṣọ́nà Tí Ń Kéde Ìjọba Jehofa—1994
  • A San Èrè fún Ìwà Títọ́ Jóòbù
    Ilé Ìṣọ́ Tí Ń Kéde Ìjọba Jehofa—1998
  • Èrè Jobu—Orísun kan Fún Ìrètí
    Ilé-Ìṣọ́nà Tí Ń Kéde Ìjọba Jehofa—1994
Àwọn Míì
Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Kristẹni—Ìwé Ìpàdé—2023
mwb23 November ojú ìwé 6

ÀWỌN ÌṢÚRA INÚ Ọ̀RỌ̀ ỌLỌ́RUN

Owó Kọ́ Ló Ń Mú Kéèyàn Jẹ́ Olódodo

Sófárì sọ pé Ọlọ́run máa ń sọ àwọn ẹni burúkú tó ní ọrọ̀ di ẹdun arinlẹ̀, ohun tó ń dọ́gbọ́n sọ ni pé Jóòbù ti ní láti ṣẹ Ọlọ́run (Job 20:​5, 10, 15)

Jóòbù dáhùn pé: ‘Kí wá ló dé tí àwọn ẹni burúkú fi ń di ọlọ́rọ̀?’ (Job 21:​7-9)

Àpẹẹrẹ Jésù jẹ́ ká mọ̀ pé àwọn tó ń sin Jèhófà tọkàntọkàn lè má lówó lọ́wọ́ (Lk 9:58)

Arákùnrin kan ń ka Bíbélì fún ìdílé kan tí ò lówó níwájú ilé wọn. Bàbá náà ń fojú bá a lọ nínú Bíbélì ẹ̀, ìyàwó àtọmọ ẹ̀ sì tẹ́tí sílẹ̀.

RONÚ LÓRÍ ÌBÉÈRÈ YÌÍ: Yálà àwọn tó ń sin Jèhófà tọkàntọkàn lówó tàbí wọn ò ní, kí ló ṣe pàtàkì sí wọn?—Lk 12:21; w07 8/1 29 ¶12.

    Yorùbá Publications (1987-2025)
    Jáde
    Wọlé
    • Yorùbá
    • Fi Ráńṣẹ́
    • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
    • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
    • Àdéhùn Nípa Lílò
    • Òfin
    • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
    • JW.ORG
    • Wọlé
    Fi Ráńṣẹ́