MÍKÀ
OHUN TÓ WÀ NÍNÚ ÌWÉ YÌÍ
1
2
3
4
5
Alákòóso kan yóò lágbára ní gbogbo ayé (1-6)
Àwọn tó ṣẹ́ kù yóò dà bí ìrì àti bíi kìnnìún (7-9)
Ọlọ́run máa fọ ilẹ̀ náà mọ́ (10-15)
6
7
Ìwàkiwà Ísírẹ́lì (1-6)
“Màá dúró de Ọlọ́run” (7)
Ọlọ́run dá àwọn èèyàn rẹ̀ láre (8-13)
Míkà gbàdúrà, ó sì yin Ọlọ́run (14-20)