ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • nwt ojú ìwé 1256
  • Ohun Tó Wà Nínú Ìwé Míkà

Kò sí fídíò kankan ní apá yìí.

Má bínú, fídíò yìí kò jáde.

  • Ohun Tó Wà Nínú Ìwé Míkà
  • Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
  • Àpilẹ̀kọ Míì Tó Jọ ọ́
  • A Óò Máa Rìn Ní Orúkọ Jèhófà Títí Láé!
    Ilé Ìṣọ́ Tí Ń Kéde Ìjọba Jehofa—2003
  • Àwọn Ìránṣẹ́ Jèhófà Ní Ìrètí Tòótọ́
    Ilé Ìṣọ́ Tí Ń Kéde Ìjọba Jehofa—2003
  • Kí Ni Jèhófà Ń Retí Pé Ká Máa Ṣe?
    Ilé Ìṣọ́ Tí Ń Kéde Ìjọba Jehofa—2003
  • Míkà 6:8—“Máa Rìn ní Ìrẹ̀lẹ̀ Pẹ̀lú Ọlọ́run Rẹ”
    Àlàyé Àwọn Ẹsẹ Bíbélì
Àwọn Míì
Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
Ohun Tó Wà Nínú Ìwé Míkà

MÍKÀ

OHUN TÓ WÀ NÍNÚ ÌWÉ YÌÍ

  • 1

    • Ohun tó máa ṣẹlẹ̀ sí Samáríà àti Júdà (1-16)

      • Ẹ̀ṣẹ̀ àti ọ̀tẹ̀ ló fa wàhálà náà (5)

  • 2

    • Àwọn tó ń ni ẹlòmíì lára gbé! (1-11)

    • Ọlọ́run tún mú kí Ísírẹ́lì wà ní ìṣọ̀kan (12, 13)

      • Ariwo àwọn èèyàn yóò gba ilẹ̀ náà kan (12)

  • 3

    • Ọlọ́run bá àwọn olórí àti àwọn wòlíì wí (1-12)

      • Ẹ̀mí Jèhófà fún Míkà ní agbára (8)

      • Àwọn àlùfáà ń gba owó kí wọ́n tó kọ́ni (11)

      • Jerúsálẹ́mù yóò di àwókù ilé (12)

  • 4

    • Òkè Jèhófà yóò ga ju àwọn yòókù lọ (1-5)

      • Wọ́n á fi idà rọ ohun ìtúlẹ̀ (3)

      • “Àwa yóò máa rìn ní orúkọ Jèhófà” (5)

    • Ọlọ́run yóò mú kí Síónì pa dà di alágbára (6-13)

  • 5

    • Alákòóso kan yóò lágbára ní gbogbo ayé (1-6)

      • Alákòóso náà yóò wá láti Bẹ́tílẹ́hẹ́mù (2)

    • Àwọn tó ṣẹ́ kù yóò dà bí ìrì àti bíi kìnnìún (7-9)

    • Ọlọ́run máa fọ ilẹ̀ náà mọ́ (10-15)

  • 6

    • Ọlọ́run pe Ísírẹ́lì lẹ́jọ́ (1-5)

    • Kí ni Jèhófà fẹ́? (6-8)

      • Ìdájọ́ òdodo, ìṣòtítọ́, ìrẹ̀lẹ̀ (8)

    • Ẹ̀bi Ísírẹ́lì àti ìyà tí wọ́n máa jẹ (9-16)

  • 7

    • Ìwàkiwà Ísírẹ́lì (1-6)

      • “Ará ilé ẹni ni ọ̀tá ẹni” (6)

    • “Màá dúró de Ọlọ́run” (7)

    • Ọlọ́run dá àwọn èèyàn rẹ̀ láre (8-13)

    • Míkà gbàdúrà, ó sì yin Ọlọ́run (14-20)

      • Jèhófà dáhùn (15-17)

      • ‘Ta ló dà bíi Jèhófà?’ (18)

    Yorùbá Publications (1987-2025)
    Jáde
    Wọlé
    • Yorùbá
    • Fi Ráńṣẹ́
    • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
    • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
    • Àdéhùn Nípa Lílò
    • Òfin
    • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
    • JW.ORG
    • Wọlé
    Fi Ráńṣẹ́