ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • scl ojú ìwé 119
  • Ọtí Mímu

Kò sí fídíò kankan ní apá yìí.

Má bínú, fídíò yìí kò jáde.

  • Ọtí Mímu
  • Àwọn Ẹsẹ Bíbélì Tó Lè Ran Àwa Kristẹni Lọ́wọ́
Àwọn Ẹsẹ Bíbélì Tó Lè Ran Àwa Kristẹni Lọ́wọ́
scl ojú ìwé 119

Ọtí Mímu

Ṣé Bíbélì sọ pé a ò gbọ́dọ̀ mutí rárá?

Sm 104:14, 15; Onw 9:7; 10:19; 1Ti 5:23

  • Àpẹẹrẹ inú Bíbélì:

    • Joh 2:1-11—Iṣẹ́ ìyanu àkọ́kọ́ tí Jésù ṣe ni pé ó sọ omi di wáìnì níbi ìgbéyàwó kan, kójú má bàa ti ọkọ àti ìyàwó náà

Kí ló lè ṣẹlẹ̀ tá a bá mutí lámujù tàbí tá a mutí yó?

Owe 20:1; 23:20, 21, 29-35; Ais 28:7; Ho 4:11

Èrò wo làwọn ìránṣẹ́ Ọlọ́run ní nípa mímu ọtí ní àmupara?

1Kọ 5:11; 6:9, 10; Ef 5:18; 1Ti 3:2, 3

  • Àpẹẹrẹ inú Bíbélì:

    • Jẹ 9:20-25—Nígbà tí Nóà mutí yó tó sì sùn lọ, ọmọ ọmọ rẹ̀ ṣe ohun tó burú gan-an

    • 1Sa 25:2, 3, 36—Nábálì jẹ́ òpònú àti ìkà, ó sì máa ń ṣe àwọn nǹkan tó burú gan-an irú bíi kó mutí yó bìnàkò

    • Da 5:1-6, 22, 23, 30, 31—Ọba Bẹliṣásárì mutí lámujù, ó sì tàbùkù sí Ọlọ́run; òru ọjọ́ yẹn ni wọ́n pa á

Tá ò bá tiẹ̀ mutí yó, kí nìdí tó fi yẹ ká kíyè sí bí ọtí tá a fẹ́ mu ṣe máa pọ̀ tó?

Owe 23:20; Ais 5:11; Lk 21:34; 1Ti 3:8

Tún wo 1Pe 4:3

Tó o bá mọ arákùnrin tàbí arábìnrin kan tó sábà máa ń mutí lámujù, báwo lo ṣe lè ràn án lọ́wọ́?

Ro 14:13, 21; 1Kọ 13:4, 5; 1Tẹ 4:4

Tún wo “Ìkóra-Ẹni-Níjàánu”

    Yorùbá Publications (1987-2025)
    Jáde
    Wọlé
    • Yorùbá
    • Fi Ráńṣẹ́
    • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
    • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
    • Àdéhùn Nípa Lílò
    • Òfin
    • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
    • JW.ORG
    • Wọlé
    Fi Ráńṣẹ́