ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • Jeremáyà 1:15
    Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
    • 15 Nítorí ‘mò ń pe gbogbo ìdílé àwọn ìjọba àríwá,’ ni Jèhófà wí,+

      ‘Wọ́n á wá, kálukú wọn á sì ṣe ìtẹ́ rẹ̀

      Sí àwọn ẹnubodè Jerúsálẹ́mù,+

      Wọ́n á gbé e ti gbogbo ògiri tó yí i ká

      Wọ́n á sì gbé e ti gbogbo ìlú tó wà ní Júdà.+

  • Jeremáyà 4:16
    Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
    • 16 Ẹ ròyìn rẹ̀, bẹ́ẹ̀ ni, ẹ ròyìn rẹ̀ fún àwọn orílẹ̀-èdè;

      Ẹ kéde rẹ̀ sórí Jerúsálẹ́mù.”

      “Àwọn ẹ̀ṣọ́* ń bọ̀ láti ilẹ̀ tó jìnnà,

      Wọ́n á sì gbé ohùn wọn sókè sí àwọn ìlú Júdà.

  • Jeremáyà 25:9
    Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
    • 9 Màá ránṣẹ́ pe gbogbo ìdílé tó wà ní àríwá,”+ ni Jèhófà wí, “màá ránṣẹ́ sí Nebukadinésárì* ọba Bábílónì, ìránṣẹ́ mi,+ màá mú wọn wá láti gbéjà ko ilẹ̀ yìí+ àti àwọn tó ń gbé lórí rẹ̀ pẹ̀lú gbogbo orílẹ̀-èdè tó yí i ká.+ Màá pa wọ́n run pátápátá, màá sì sọ wọ́n di ohun àríbẹ̀rù àti ohun àrísúfèé àti ibi àwókù títí láé.

  • Ìsíkíẹ́lì 7:24
    Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
    • 24 Màá mú orílẹ̀-èdè tó burú jù wá,+ wọ́n á sì gba àwọn ilé wọn,+ màá fòpin sí ìgbéraga àwọn alágbára, àwọn ibi mímọ́ wọn á sì di aláìmọ́.+

  • Hábákúkù 1:6
    Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
    •  6 Mò ń gbé àwọn ará Kálídíà dìde,+

      Orílẹ̀-èdè tí kò lójú àánú, tí kì í fi nǹkan falẹ̀.

      Wọ́n yára bolẹ̀ káàkiri ayé

      Láti gba àwọn ilé tí kì í ṣe tiwọn.+

Yorùbá Publications (1987-2025)
Jáde
Wọlé
  • Yorùbá
  • Fi Ráńṣẹ́
  • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
  • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
  • Àdéhùn Nípa Lílò
  • Òfin
  • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
  • JW.ORG
  • Wọlé
Fi Ráńṣẹ́