Àìsáyà 1:15 Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun 15 Tí ẹ bá sì tẹ́ ọwọ́ yín,Mò ń fojú mi pa mọ́ fún yín.+ Bí ẹ tiẹ̀ ń gbàdúrà púpọ̀,+Mi ò gbọ́ àdúrà yín;+Ẹ̀jẹ̀ kún ọwọ́ yín.+ Àìsáyà 58:3 Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun 3 ‘Kí ló dé tí o ò rí i nígbà tí à ń gbààwẹ̀?+ Kí ló sì dé tí o ò kíyè sí i nígbà tí à ń pọ́n ara* wa lójú?’+ Torí ní ọjọ́ tí ẹ̀ ń gbààwẹ̀, ire* ara yín lẹ̀ ń wá,Ẹ sì ń fìyà jẹ àwọn alágbàṣe yín.+ Jeremáyà 11:11 Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun 11 Torí náà, ohun tí Jèhófà sọ nìyí, ‘Wò ó, màá mú àjálù+ tí wọn kò ní lè bọ́ nínú rẹ̀ wá bá wọn. Nígbà tí wọ́n bá ké pè mí fún ìrànlọ́wọ́, mi ò ní fetí sí wọn.+ Ìsíkíẹ́lì 8:18 Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun 18 Torí náà, màá bínú sí wọn. Mi ò ní ṣàánú wọn, mi ò sì ní yọ́nú sí wọn.+ Bí wọ́n bá tiẹ̀ kígbe tantan kí n lè gbọ́, mi ò ní dá wọn lóhùn.”+
15 Tí ẹ bá sì tẹ́ ọwọ́ yín,Mò ń fojú mi pa mọ́ fún yín.+ Bí ẹ tiẹ̀ ń gbàdúrà púpọ̀,+Mi ò gbọ́ àdúrà yín;+Ẹ̀jẹ̀ kún ọwọ́ yín.+
3 ‘Kí ló dé tí o ò rí i nígbà tí à ń gbààwẹ̀?+ Kí ló sì dé tí o ò kíyè sí i nígbà tí à ń pọ́n ara* wa lójú?’+ Torí ní ọjọ́ tí ẹ̀ ń gbààwẹ̀, ire* ara yín lẹ̀ ń wá,Ẹ sì ń fìyà jẹ àwọn alágbàṣe yín.+
11 Torí náà, ohun tí Jèhófà sọ nìyí, ‘Wò ó, màá mú àjálù+ tí wọn kò ní lè bọ́ nínú rẹ̀ wá bá wọn. Nígbà tí wọ́n bá ké pè mí fún ìrànlọ́wọ́, mi ò ní fetí sí wọn.+
18 Torí náà, màá bínú sí wọn. Mi ò ní ṣàánú wọn, mi ò sì ní yọ́nú sí wọn.+ Bí wọ́n bá tiẹ̀ kígbe tantan kí n lè gbọ́, mi ò ní dá wọn lóhùn.”+