ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • w99 12/15 ojú ìwé 31
  • Atọ́ka Kókó Àpilẹ̀kọ Fún Ilé Ìṣọ́ 1999

Kò sí fídíò kankan ní apá yìí.

Má bínú, fídíò yìí kò jáde.

  • Atọ́ka Kókó Àpilẹ̀kọ Fún Ilé Ìṣọ́ 1999
  • Ilé Ìṣọ́ Tí Ń Kéde Ìjọba Jehofa—1999
  • Ìsọ̀rí
  • ÀWỌN ẸLẸ́RÌÍ JÈHÓFÀ
  • ÀWỌN OLÙPÒKÌKÍ ÌJỌBA RÒYÌN
  • BÍBÉLÌ
  • ÌBÉÈRÈ LÁTI ỌWỌ́ ÀWỌN ÒǸKÀWÉ
  • ÌGBÉSÍ AYÉ ÀTI ÀNÍMỌ́ KRISTẸNI
  • ÌTÀN ÌGBÉSÍ AYÉ
  • JÈHÓFÀ
  • JÉSÙ KRISTI
  • LÁJORÍ ÀPILẸ̀KỌ FÚN ÌKẸ́KỌ̀Ọ́
  • Ọ̀KAN-Ò-JỌ̀KAN
  • WỌ́N ṢE ÌFẸ́ JÈHÓFÀ
Ilé Ìṣọ́ Tí Ń Kéde Ìjọba Jehofa—1999
w99 12/15 ojú ìwé 31

Atọ́ka Kókó Àpilẹ̀kọ Fún Ilé Ìṣọ́ 1999

Ó ń tọ́ka sí ìtẹ̀jáde tí àpilẹ̀kọ kọ̀ọ̀kan ti jáde

ÀWỌN ẸLẸ́RÌÍ JÈHÓFÀ

“Àbẹ̀wò Mi sí Gbọ̀ngàn Ìjọba,” 11/15

Àlàáfíà ní Orílẹ̀-Èdè Tó Kún fún Wàhálà (Northern Ireland), 12/15

Àpéjọpọ̀ Àgbègbè “Ọ̀nà Ìgbésí Ayé Tí Ọlọ́run Fẹ́,” 1/15

Àpéjọpọ̀ Àgbègbè “Ọ̀rọ̀ Àsọtẹ́lẹ̀ Ọlọ́run,” 2/15

Àwọn Aláṣẹ Gbóríyìn, 4/1

Ayẹyẹ Ìkẹ́kọ̀ọ́yege ní Gilead, 6/1, 12/15

“Ẹ Ti Yí Èrò Mi Padà,” 9/15

Ìbẹ̀wò Pàtàkì Mú Erékùṣù Kan Yọ̀ Ṣẹ̀ṣẹ̀ (Cuba), 5/15

Ìfẹ́ Tí A Ní sí “Àwọn Tí Ó Bá Wa Tan Nínú Ìgbàgbọ́” (ìjábá Chile), 6/15

Ilẹ̀ Àwọn Venda Abèso Wọ̀ǹtìwọnti, 5/1

‘Iná Ẹ̀mí Ìtọpinpin’ (ìwé Creator), 6/15

Ìyàsímímọ́ Ibùdó Ìdánilẹ́kọ̀ọ́ ti Watchtower, 11/15

Namibia, 7/15

Nígbà Tí Ìwà Ọ̀làwọ́ Bá Pọ̀ Gidigidi (ọrẹ), 11/1

Ǹjẹ́ O Lè Sìn ní Ilẹ̀ Òkèèrè? 10/15

‘Ọkọ Tó Láyọ̀ Nítorí Tí Ó Ní Aya Rere,’ 9/1

St. Helena, 2/1

ÀWỌN OLÙPÒKÌKÍ ÌJỌBA RÒYÌN

2/1, 4/1, 6/1, 8/1, 12/1

BÍBÉLÌ

Gbára Lé Àsọtẹ́lẹ̀ Bíbélì, 7/15

Ìṣẹ̀lẹ̀ Mánigbàgbé Fáwọn Tó Fẹ́ràn Ọ̀rọ̀ Ọlọ́run (Ìtumọ̀ Ayé Tuntun), 10/15

Jerome—Òléwájú Nínú Ìtumọ̀ Bíbélì, 1/1

Ǹjẹ́ Ó Lè Ràn Wá Lọ́wọ́ Lóde Òní? 11/15

Ọ̀rọ̀ Ọgbọ́n fún Òde Ìwòyí, 4/1

Ṣíṣàlàyé Bíbélì—Ta Ló Ń Darí Rẹ̀? 8/1

ÌBÉÈRÈ LÁTI ỌWỌ́ ÀWỌN ÒǸKÀWÉ

Ìfẹ́sọ́nà, 8/15

Iṣẹ́ abẹ sísọni di aláìlèbímọ fún ìfètòsọ́mọbíbí, 6/15

Iṣẹ́ tó ní í ṣe pẹ̀lú ilé ìjọsìn, 4/15

‘Sísàmì’ (2 Tẹ 3:14), 7/15

ÌGBÉSÍ AYÉ ÀTI ÀNÍMỌ́ KRISTẸNI

A Fún Wọn Lókun Láti Sọ Pé A Ò Jẹ́ Hùwà Àìtọ́, 10/1

Àwọn Èèyàn Ha Ń Gba Ìmọ̀ràn Rẹ Bí? 1/15

Àwọn Ìdílé Ńlá Tó Ṣọ̀kan Nínú Iṣẹ́ Ìsìn Ọlọ́run, 2/15

Báa Ṣe Lè Mọ Àìlera Tẹ̀mí Kí A sì Borí Rẹ̀, 4/15

Èé Ṣe Tó Fi Yẹ Kóo Máa Mú Ìlérí Rẹ Ṣẹ? 9/15

Ẹ̀mí Ìrẹ̀lẹ̀, 2/1

Ẹ̀mí Ṣohun-Tẹ́gbẹ́-Ń-Ṣe, 8/1

“Fi Ìbùkún fún Jèhófà, Ìwọ Ọkàn Mi,” 5/15

Ìdílé Onígbeyàwó Àtúnṣe Lè Ṣàṣeyọrí, 3/1

Ìgbéyàwó Aláṣeyọrí, 2/15

Ìjọ Kristẹni—Àrànṣe Afúnnilókun, 5/15

Ìjùmọ̀sọ̀rọ̀—Àṣírí Ìgbéyàwó Aláṣeyọrí, 7/15

Ìrẹ̀wẹ̀sì, 11/15

Jẹ́ Kí Òye Rẹ Kún? 6/15

Jíjàǹfààní Látinú “Ọkà Ọ̀run,” 8/15

Kíkọ́ Ìfẹ́ Títayọ, 10/15

Máa Fi Hàn Pé O Moore, 4/15

Máà Jẹ́ Kí Àníyàn Borí Rẹ, 3/15

Máà Jẹ́ Kí Ìbínú Mú Ọ Kọsẹ̀, 8/15

Máa Kàwé Pẹ̀lú Àwọn Ọmọ Rẹ, 5/1

Má Ṣe Jẹ́ Kí Ànímọ́ Rere Rẹ Di Àbùkù Rẹ, 12/1

Ní Ọgbọ́n, Kí O Sì Gba Ìbáwí, 9/15

Rírú Ẹbọ Tí Jèhófà Yóò Tẹ́wọ́ Gbà, 2/1

Ṣé Ojú Tí Ọlọ́run Fi Ń Wo Àwọn Oníwà Ipá? 12/15

Ta Ló Ń Darí Èrò Rẹ? 4/1

ÌTÀN ÌGBÉSÍ AYÉ

“Aṣiṣẹ́ Tí Kò Ní Ohun Kankan Láti Tì í Lójú” (A. Soppa), 1/1

Àwọn Òbí Wa Kọ́ Wa Láti Nífẹ̀ẹ́ Ọlọ́run (E. Tracy), 12/1

Fífi Tayọ̀tayọ̀ Tẹ́wọ́ Gba Ìdarí Jèhófà (U. Glass), 8/1

Fífún Jèhófà Ní Ohun Tó Tọ́ Sí I (T. Vasiliou), 10/1

Jèhófà Jẹ́ Ọlọ́run Olóore sí Mi (J. Andronikos), 11/1

Jèhófà Ti Jẹ́ Àpáta Gàǹgà Mi (E. Lionoudakis), 9/1

Láti Inú Ipò Òṣì Paraku, Mo Bọ́ Sínú Ọrọ̀ (M. Almeida), 7/1

Mímú Ìlérí Mi Láti Sin Ọlọ́run Ṣẹ (F. Gudlikies), 6/1

Mò Ń Wá Párádísè Kiri (P. Stisi), 4/1

Ó Lé Lógójì Ọdún Táa Fi Wà Lábẹ́ Ìfòfindè (M. V. Savitskii), 3/1

Ó Ṣèrànwọ́ Láti Tan Ìmọ́lẹ̀ (L. Barry), 10/1

Yíyọ̀ Láìka Àwọn Àdánwò Sí (G. Scipio), 2/1

JÈHÓFÀ

A Mú Orúkọ Náà Padà Bọ̀ Sípò, 3/1

A Pe Orúkọ Àtọ̀runwá Náà ní Ísírẹ́lì, 7/1

“Jèhófà Fúnra Rẹ̀ Ní Ń Fúnni Ní Ọgbọ́n,” 11/15

Kò Fi Nǹkan Falẹ̀, 6/1

Ṣé “Jèhófà” Ni, Àbí “Yahweh”? 2/1

Ṣe Nǹkan Lọ́nà “Wíwọ́” Bí? 5/1

JÉSÙ KRISTI

Bí Jésù Ṣe Lè Yí Ìgbésí Ayé Rẹ Padà, 7/1

Ọjọ́ Tí Ó Lò Kẹ́yìn Gẹ́gẹ́ Bí Ènìyàn, 3/15

Ọkùnrin Títóbilọ́lá Jù Lọ Ṣe Iṣẹ́ Rírẹlẹ̀, 3/1

LÁJORÍ ÀPILẸ̀KỌ FÚN ÌKẸ́KỌ̀Ọ́

Atóbilọ́lá Amọ̀kòkò Náà àti Iṣẹ́ Rẹ̀, 2/1

Àwọn Àǹfààní Tó Wà Nínú Nínífẹ̀ẹ́ Ọ̀rọ̀ Ọlọ́run, 11/1

“Àwọn Ẹ̀bùn Tí Ó Jẹ́ Ènìyàn” Láti Máa Bójú Tó Àwọn Àgùntàn Jèhófà, 6/1

Báwo Lo Ṣe Nífẹ̀ẹ́ Ọ̀rọ̀ Ọlọ́run Tó? 11/1

“Ẹ Fìdí Ọkàn-Àyà Yín Múlẹ̀ Gbọn-in,” 1/1

“Ẹ Fi Ìrẹ̀lẹ̀ Èrò Inú Di Ara Yín Lámùrè,” 8/1

Ẹ Jẹ́ Ká Wà Lára Àwọn Tó Ní Ìgbàgbọ́, 12/15

Ẹlẹ́dàá Lè Mú Kí Ayé Rẹ Nítumọ̀, 6/15

Ẹ Máa Bọlá Fáwọn Ẹlòmíràn, 8/1

Ẹ Máa Dárí Jini Látọkàn Wá, 10/15

Ẹ Máa Gbé Ọwọ́ Ìdúróṣinṣin Sókè Nínú Àdúrà, 1/15

Ẹ Wà Lójúfò, Kí Ẹ Sì Jẹ́ Aláápọn! 5/1

Ẹ̀yin Ìdílé, Ẹ Máa Yin Ọlọ́run Gẹ́gẹ́ Bí Apá Kan Ìjọ Rẹ̀, 7/1

Ẹ̀yin Òbí, Ẹ̀kọ́ Wo Làpẹẹrẹ Yín Ń Kọ́ni? 7/1

Ẹ̀yin Ọ̀dọ́—Ẹ Dènà Ẹ̀mí Ayé, 9/1

Ẹ̀yin Ọ̀dọ́—Ẹ Kọ́ Agbára Ìwòye Yín! 9/1

“Fi Ọkàn-Àyà Rẹ Sí” Tẹ́ńpìlì Ọlọ́run! 3/1

Ìbùkún Jèhófà Lórí “Ilẹ̀” Wa, 3/1

“Ìgbà Àlàáfíà” Ti Fẹ́rẹ̀ẹ́ Dé! 10/1

Inú Wa Dùn Pé Jèhófà Ń Fọ̀nà Rẹ̀ Hàn Wá, 5/15

Ìràpadà Kristi—Ọ̀nà Tí Ọlọ́run Là Sílẹ̀ fún Ìgbàlà, 2/15

Ìrètí Ló Mú Wa Dúró, Ìfẹ́ Ló Ń Sún Wa Ṣiṣẹ́, 7/15

Ìṣúra Wa Ń Bẹ Nínú Ohun Èlò Tí A Fi Amọ̀ Ṣe, 2/1

Ìwàláàyè Lẹ́yìn Ikú—Kí Ni Bíbélì Sọ Nípa Rẹ̀? 4/1

Ìwàláàyè Lẹ́yìn Ikú—Kí Ni Ìgbàgbọ́ Àwọn Ènìyàn? 4/1

Ìyè Àìnípẹ̀kun Ha Ṣeé Ṣe Lóòótọ́ Bí? 4/15

Jèhófà Ń Ṣètò Sílẹ̀, 8/15

Jẹ́ Ẹni Tí Ń Fi Ayọ̀ Ka Ìwé Ìṣípayá, 12/1

Kẹ́sẹ Járí Nínú Ìgbésí Ayé Rẹ! 9/1

Kí A Má Ṣe Fà Sẹ́yìn sí Ìparun! 12/15

Kíkẹ́kọ̀ọ́ Ọ̀rọ̀ Ọlọ́run Déédéé Gẹ́gẹ́ Bí Ìdílé, 7/1

Kí Ni Jèhófà Ń Béèrè Lọ́wọ́ Wa Lónìí? 9/15

“Kí Òǹkàwé Lo Ìfòyemọ̀,” 5/1

“Làbárè Amúniyọ̀ṣẹ̀ṣẹ̀” Látinú Ìwé Ìṣípayá, 12/1

Lílo Ìgbàgbọ́ Nínú Àwọn Ìlérí Ọlọ́run, 8/15

Máa Fiyè sí Ẹ̀kọ́ Rẹ Nígbà Gbogbo, 3/15

Máa Lo Ìjìnlẹ̀ Òye àti Ìyíniléròpadà Tóo Bá Ń Kọ́ni, 3/15

Máa Rìn ní Ọ̀nà Jèhófà, 5/15

Mímọrírì “Àwọn Ẹ̀bùn Tí Ó Jẹ́ Ènìyàn,” 6/1

Mọ Irú Ẹni Tí Ẹlẹ́dàá Rẹ Jẹ́, 6/15

Ǹjẹ́ O Nígbàgbọ́ Bíi Ti Ábúráhámù? 1/1

Ǹjẹ́ Ò Ń Ṣe Gbogbo Ojúṣe Rẹ Níwájú Ọlọ́run? 11/15

“Nǹkan Wọ̀nyí Gbọ́dọ̀ Ṣẹ,” 5/1

O Ha ‘Ń Pèsè Àdúrà Rẹ Bíi Tùràrí’ Bí? 1/15

“Ohun Gbogbo Ni Ìgbà Tí A Yàn Kalẹ̀ Wà Fún,” 10/1

O Lè Fara Dà Á Dé Òpin, 10/1

O Lè Jèrè Arákùnrin Rẹ, 10/15

Ọ̀nà Ìfẹ́ Kì Í Kùnà, 2/15

Ọ̀nà Kan Ṣoṣo Tó Lọ sí Ìyè Àìnípẹ̀kun, 4/15

Rántí Ẹlẹ́dàá Rẹ Atóbilọ́lá! 11/15

Ríran Àwọn Ènìyàn Lọ́wọ́ Láti Sún Mọ́ Jèhófà, 7/15

Ṣé Ohun Tí Jèhófà Ń Béèrè Lọ́wọ́ Wa Pọ̀ Jù Ni? 9/15

“Tẹ́ńpìlì Náà” àti “Ìjòyè Náà” Lónìí, 3/1

Ọ̀KAN-Ò-JỌ̀KAN

Àkókò àti Ayérayé, 6/1

Àsọtẹ́lẹ̀ Inú Ìwé Ìṣípayá—Ṣé Ká Máa Bẹ̀rù Rẹ̀ Ni Àbí? 12/1

Àwọn Alábàáṣiṣẹ́pọ̀ Pọ́ọ̀lù, 6/1

Àwọn Àlọ́ Tí Ọlọ́run Mí Sí, 10/1

Àwọn Kọ́líjéètì, 4/15

Báwo La Ṣe Lè Pẹ́ Tó Láyé? 4/15

Èé Ṣe Tí Àkókò Fi Kéré Tó Bẹ́ẹ̀? 10/1

Èrè Ìgbéraga, 2/1

Ẹgbẹ̀rúndún Tó Ṣe Pàtàkì, 11/1

Ẹ̀mí Kẹ́lẹ́yàmẹ̀yà àti Ìsìn, 8/1

Ẹ̀tọ́ Ọgbọọgba, 8/1

Fílípì—Ajíhìnrere Tó Nítara, 7/15

Gbogbo Èèyàn Yóò Lómìnira, 5/1

Gbogbo Kìràkìtà Wa Láti Pẹ́ Láyé, 10/15

Ìjọsìn Báálì, 4/1

Ìmọ̀ Ọgbọ́n Gíríìkì—Ṣé Ó Ṣe Ẹ̀sìn Kristẹni Lóore? 8/15

Ìwà Bàsèjẹ́, 6/15

“Ìyálóde Aginjù Síríà Abirun-Dúdú Mìnìjọ̀” (Senobíà), 1/15

Ìyè Wù Ọ́, 8/15

“Iyọ̀ Pàdánù Okun Rẹ̀,” 8/15

Kérésìmesì ní Ìlà Oòrùn Ayé, 12/15

Lo Àkókò Pẹ̀lú Ìdílé Rẹ, 5/15

“Nínú Àwọn Ewu Odò,” 3/15

Ǹjẹ́ Ẹnikẹ́ni Tiẹ̀ Bìkítà? 9/15

Òfin Àtẹnudẹ́nu (Ìsìn Àwọn Júù), 1/15

Ojúlówó Ìrànwọ́ fún Ìdílé, 1/1

Òkè Athos—Ṣé “Òkè Mímọ́” Ni? 12/1

Ọdún 2000—Ṣọ́dún Abàmì Ni? 11/1

Rashi—Ògúnnágbòǹgbò Alálàyé Bíbélì, 3/15

Sílà—Orísun Ìṣírí, 2/15

Sọ́ọ̀lù (Pọ́ọ̀lù), 5/15, 6/15

Ṣé Èṣù Ló Ń Jẹ́ Ká Ṣàìsàn Ni? 9/1

Tímótì—“Ojúlówó Ọmọ Nínú Ìgbàgbọ́,” 9/15

Wọ́n Kọ́lé Sórí Ìpìlẹ̀ Àwọn Abọ̀rìṣà, 3/15

Wọ́n Ń Jà Nítorí Ibi “Mímọ́,” 2/15

WỌ́N ṢE ÌFẸ́ JÈHÓFÀ

Ìbẹ̀wò Kan Tó Lérè Púpọ̀ (Ọbabìnrin Ṣébà), 7/1

Ìdáríjì (Jósẹ́fù), 1/1

Màríà Yan “Ìpín Rere,” 9/1

Ọkùnrin Títóbilọ́lá Jù Lọ Ṣe Iṣẹ́ Rírẹlẹ̀ (Jésù), 3/1

Ọrẹ Àtinúwá Láti Gbé Ìjọsìn Mímọ́ Ga, 11/1

Pọ́ọ̀lù Borí Ìpọ́njú, 5/1

    Yorùbá Publications (1987-2025)
    Jáde
    Wọlé
    • Yorùbá
    • Fi Ráńṣẹ́
    • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
    • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
    • Àdéhùn Nípa Lílò
    • Òfin
    • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
    • JW.ORG
    • Wọlé
    Fi Ráńṣẹ́