- 
	                        
            
            Jeremáyà 30:10, 11Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
- 
                            - 
                                        10 “Ní tìrẹ, ìwọ Jékọ́bù ìránṣẹ́ mi, má fòyà,” ni Jèhófà wí, “Má sì jẹ́ kí ẹ̀rù bà ọ́, ìwọ Ísírẹ́lì.+ Nítorí màá gbà ọ́ láti ibi tó jìnnà réré Àti àwọn ọmọ rẹ láti oko ẹrú tí wọ́n wà.+ Jékọ́bù á pa dà, ara rẹ̀ á balẹ̀, kò ní rí ìyọlẹ́nu, Ẹnì kankan ò sì ní dẹ́rù bà wọ́n.”+ 11 “Nítorí mo wà pẹ̀lú rẹ,” ni Jèhófà wí, “láti gbà ọ́. 
 
-