-
Jeremáyà 30:10, 11Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
-
-
10 “Ní tìrẹ, ìwọ Jékọ́bù ìránṣẹ́ mi, má fòyà,” ni Jèhófà wí,
“Má sì jẹ́ kí ẹ̀rù bà ọ́, ìwọ Ísírẹ́lì.+
Nítorí màá gbà ọ́ láti ibi tó jìnnà réré
Àti àwọn ọmọ rẹ láti oko ẹrú tí wọ́n wà.+
Jékọ́bù á pa dà, ara rẹ̀ á balẹ̀, kò ní rí ìyọlẹ́nu,
Ẹnì kankan ò sì ní dẹ́rù bà wọ́n.”+
11 “Nítorí mo wà pẹ̀lú rẹ,” ni Jèhófà wí, “láti gbà ọ́.
-